< Jeremiah 36 >

1 Ní ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wí pé:
Mwaka-inĩ wa ĩna kuuma Jehoiakimu mũrũ wa Josia atuĩka mũthamaki wa Juda-rĩ, ndũmĩrĩri ĩno nĩyakinyĩire Jeremia yumĩte harĩ Jehova, akĩĩrwo ũũ:
2 “Mú ìwé kíká fún ará rẹ, kí o sì kọ sínú rẹ̀ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ nípa Israẹli àti ti Juda, àti sí gbogbo orílẹ̀-èdè láti ìgbà tí mo ti sọ fún ọ láti ọjọ́ Josiah títí di òní.
“Oya ibuku rĩa gĩkũnjo wandĩke thĩinĩ warĩo mohoro marĩa mothe ngũheete makoniĩ Isiraeli na Juda, o hamwe na ndũrĩrĩ iria ingĩ ciothe, kuuma ihinda rĩrĩa ndambĩrĩirie gũkwarĩria hĩndĩ ya wathani wa Josia, o nginya ũmũthĩ.
3 Ó lè jẹ́ wí pé ilé Juda yóò gbọ́ gbogbo ibi tí mo ti pinnu láti ṣe fún wọn; kí wọn kí ó sì yípadà, olúkúlùkù wọn kúrò ní ọ̀nà búburú rẹ̀. Kí èmi kí ó lè dárí àìṣedéédéé àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n.”
Hihi rĩrĩa andũ a Juda makaigua ũhoro wa mwanangĩko ũrĩa wothe njiirĩire kũmarehithĩria-rĩ, mũndũ o mũndũ wao ahota kũgarũrũka atigane na mĩthiĩre yake ya waganu; na niĩ nĩngamarekera waganu wao na mehia mao.”
4 Nígbà náà ni Jeremiah pe Baruku ọmọ Neriah, ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí Ọlọ́run bá a sọ fún, Baruku sì kọ láti ẹnu Jeremiah, gbogbo ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó ti sọ fún un sórí ìwé kíká náà.
Nĩ ũndũ ũcio Jeremia agĩĩta Baruku mũrũ wa Neria, nake Jeremia akĩmwĩra maũndũ marĩa mothe Jehova aamwarĩirie, nake Baruku akamandĩka ibuku-inĩ rĩu rĩa gĩkũnjo.
5 Nígbà náà ni Jeremiah wí fún Baruku pé, “A sé mi mọ́! Èmi kò lè lọ sí ilé Olúwa.
Hĩndĩ ĩyo Jeremia akĩĩra Baruku atĩrĩ, “Niĩ ndĩmuohe; ndingĩhota gũthiĩ hekarũ-inĩ ya Jehova.
6 Nítorí náà, ìwọ lọ sí ilé Olúwa ní ọjọ́ àwẹ̀, kí o sì kà nínú ìwé kíká náà ọ̀rọ̀ Olúwa tí ìwọ ti ẹnu mi kọ; ìwọ ó sì kà á ní etí gbogbo Juda, tí wọ́n jáde wá láti ìlú wọn.
Nĩ ũndũ ũcio thiĩ arĩ we kũu nyũmba-inĩ ya Jehova mũthenya ũmwe ũrĩa kwĩhingagwo kũrĩa irio, nawe ũthomere andũ acio kuuma ibuku-inĩ rĩĩrĩ rĩa gĩkũnjo maũndũ marĩa maarĩtio nĩ Jehova, macio wee wandĩkire o ta ũrĩa niĩ ndaakwĩraga wandĩke.
7 Ó lè jẹ́ pé, ẹ̀bẹ̀ wọn yóò wá sí iwájú Olúwa, wọ́n ó sì yípadà kúrò ní ọ̀nà búburú wọn; nítorí pé títóbi ni ìbínú àti ìrunú tí Olúwa ti sọ sí àwọn ènìyàn yìí.”
Hihi maahota kũrehe mathaithana mao harĩ Jehova, na o mũndũ wao atigane na mĩthiĩre yake ya waganu, nĩ ũndũ marakara na mangʼũrĩ marĩa matuĩrĩirwo andũ aya nĩ Jehova nĩ manene.”
8 Baruku ọmọ Neriah sì ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí wòlíì Jeremiah sọ fún, láti ka ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé ní ilé Olúwa.
Nake Baruku mũrũ wa Neria nĩekire ũrĩa wothe Jeremia ũrĩa mũnabii aamwĩrĩte eeke; agĩthoma ndũmĩrĩri ĩyo ya Jehova kũu thĩinĩ wa hekarũ kuuma ibuku-inĩ rĩu rĩa gĩkũnjo.
9 Ní oṣù kẹsànán ọdún karùn-ún Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda ni wọ́n kéde àwẹ̀ níwájú Olúwa fún gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu àti fún gbogbo àwọn ènìyàn tí ó wá láti ìlú Juda.
Na rĩrĩ, mweri-inĩ wa kenda wa mwaka wa ĩtano wa wathani wa Jehoiakimu mũrũ wa Josia mũthamaki wa Juda, ihinda rĩa kwĩhinga kũrĩa irio mbere ya Jehova nĩrĩanĩrĩirwo kũrĩ andũ othe a Jerusalemu, o na arĩa angĩ othe mookĩte kuuma matũũra ma Juda.
10 Láti inú yàrá Gemariah ọmọ Ṣafani akọ̀wé, ní àgbàlá òkè níbi ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tuntun. Baruku sì ka ọ̀rọ̀ Jeremiah láti inú ìwé ní ilé Olúwa sí etí gbogbo ènìyàn.
Kuuma kanyũmba-inĩ ka Gemaria mũrũ wa Shafani ũrĩa mwandĩki, karĩa kaarĩ o kũu nja ya na igũrũ, itoonyero-inĩ rĩa Kĩhingo kĩrĩa Kĩerũ kĩa hekarũ, Baruku agĩthomera andũ othe ciugo cia Jeremia kuuma ibuku-inĩ rĩu rĩa gĩkũnjo kũu hekarũ-inĩ ya Jehova.
11 Nígbà tí Mikaiah ọmọ Gemariah ọmọ Ṣafani gbọ́ gbogbo àkọsílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé náà;
Rĩrĩa Mikaia mũrũ wa Gemaria, mũrũ wa Shafani aiguire ndũmĩrĩri ĩyo ya Jehova yothe kuuma ibuku-inĩ rĩu rĩa gĩkũnjo-rĩ,
12 Ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé ọba sínú yàrá akọ̀wé; níbi tí gbogbo àwọn ìjòyè gbé jókòó sí: Eliṣama akọ̀wé, Delaiah ọmọ Ṣemaiah, Elnatani ọmọ Akbori, Gemariah ọmọ Ṣafani àti Sedekiah ọmọ Hananiah àti gbogbo àwọn ìjòyè.
agĩikũrũka agĩtoonya kanyũmba-inĩ ka mwandĩki karĩa kaarĩ kũu nyũmba-inĩ ya ũthamaki, harĩa anene othe maikarĩte, nao nĩo: Elishama ũrĩa mwandĩki, na Delia mũrũ wa Shemaia, na Elinathani mũrũ wa Akibori, na Gemaria mũrũ wa Shafani, na Zedekia mũrũ wa Hanania, na anene arĩa angĩ othe.
13 Lẹ́yìn tí Mikaiah sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì tí o ti gbọ́ fún wọn, nígbà tí Baruku kà láti inú ìwé kíkà náà ní etí àwọn ènìyàn.
Mikaia aarĩkia kũmahe ũhoro wothe ũrĩa aiguĩte Baruku agĩthomera andũ kuuma ibuku-inĩ rĩa gĩkũnjo-rĩ,
14 Gbogbo àwọn ìjòyè sì rán Jehudu ọmọ Netaniah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Kuṣi sí Baruku wí pé, mú ìwé kíká náà ní ọwọ́ rẹ láti inú èyí tí ìwọ kà ní etí àwọn ènìyàn; kí o si wá. Nígbà náà ni Baruku ọmọ Neriah wá sí ọ̀dọ̀ wọn pẹ̀lú ìwé kíká ní ọwọ́ rẹ̀.
anene acio othe magĩtũma Jehudi mũrũ wa Nethania, mũrũ wa Shelemia, mũrũ wa Kushi, athiĩ akeere Baruku atĩrĩ, “Oya ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo, rĩu ũthomeire andũ, ũũke narĩo.” Nĩ ũndũ ũcio Baruku mũrũ wa Neria agĩthiĩ hau maarĩ anyiitĩte ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo na guoko gwake.
15 Wọ́n sì wí fún pé, “Jókòó, jọ̀wọ́ kà á sí etí wa!” Nígbà náà ni Baruku sì kà á ní etí wọn.
Nao makĩmwĩra atĩrĩ, “Rĩu ta ikara thĩ, ũtũthomere.” Nĩ ũndũ ũcio Baruku akĩmathomera.
16 Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ náà tan; wọ́n ń wo ara wọn lójú pẹ̀lú ẹ̀rù. Wọ́n sì wí fún Baruku pé, “Àwa gbọdọ̀ jábọ̀ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún ọba.”
Rĩrĩa maaiguire mohoro macio mothe, makĩrorana marĩ na guoya, makĩĩra Baruku atĩrĩ, “No nginya tũkinyĩrie mũthamaki ũhoro ũcio wothe.”
17 Wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ Baruku pé, “Sọ fún wa báwo ni o ṣe kọ gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí? Ṣé Jeremiah ló sọ wọ́n?”
Ningĩ magĩcooka makĩũria Baruku atĩrĩ, “Ta twĩre, maũndũ macio mothe wamandĩkire atĩa? Nĩ Jeremia wakwĩraga nawe ũkamaandĩka?”
18 Baruku sì dá wọn lóhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, láti ẹnu rẹ̀ ni, ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ báyìí fún mi, èmi sì fi tàdáwà kọ wọ́n sínú ìwé náà.”
Baruku akĩmacookeria atĩrĩ, “Ĩĩ, nĩwe wanjĩĩraga mohoro macio mothe, na niĩ ngamaandĩka na rangi ibuku-inĩ rĩĩrĩ rĩa gĩkũnjo.”
19 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè sọ fún Baruku wí pé, “Lọ fi ara rẹ pamọ́ àti Jeremiah, má sì ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ibi tí ẹ̀yin wà.”
Nao anene acio makĩĩra Baruku atĩrĩ, “Wee na Jeremia thiĩi mwĩhithe. Mũtikareke mũndũ o na ũ amenye kũrĩa mũrĩ.”
20 Lẹ́yìn tí wọ́n fi ìwé kíká náà pamọ́ sí iyàrá Eliṣama akọ̀wé, wọ́n sì wọlé tọ ọba lọ nínú àgbàlá, wọ́n sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà ní etí ọba.
Maarĩkia kũiga ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo kanyũmba-inĩ ka Elishama, ũrĩa mwandĩki, magĩtoonya harĩa mũthamaki aarĩ kũu nyũmba yake ya thĩinĩ makĩmũhe ũhoro ũcio wothe.
21 Ọba sì rán Jehudu láti lọ mú ìwé kíká náà wá, Jehudu sì mu jáde láti inú iyàrá Eliṣama akọ̀wé. Ó sì ka ìwé náà ní etí ọba àti ní etí gbogbo àwọn ìjòyè tí ó dúró ti ọba.
Mũthamaki nake agĩtũma Jehudi agĩĩre ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo, nake Jehudi akĩrĩrehe kuuma kanyũmba-inĩ ka Elishama, ũrĩa mwandĩki, akĩrĩthomera mũthamaki na anene acio othe marũgamĩte hau harĩ mũthamaki.
22 Ó sì jẹ́ ìgbà òtútù nínú oṣù kẹsànán, ọba sì jókòó ní ẹ̀bá iná ààrò, iná náà sì ń jó ní iwájú rẹ̀.
Kwarĩ mweri wa kenda, nake mũthamaki aikarĩte nyũmba-inĩ ĩrĩa aikaraga hĩndĩ ya kĩmera kĩa heho, na haarĩ na mwaki waakanaga riiko-inĩ hau mbere yake.
23 Nígbà tí Jehudu ka ojú ìwé mẹ́ta sí mẹ́rin nínú ìwé náà, ọba fi ọ̀bẹ gé ìwé, ó sì sọ sínú iná tí ó wà nínú ìdáná, títí tí gbogbo ìwé kíká náà fi jóná tán.
Jehudi aathoma icigo ithatũ kana inya cia ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo-rĩ, mũthamaki nake agacitinia na kahiũ ka mwandĩki, agacikia riiko-inĩ, o nginya rĩrĩa ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo rĩacinirwo rĩothe.
24 Síbẹ̀, ọba àti gbogbo àwọn ẹ̀mẹwà rẹ̀ tí wọ́n gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí kò bẹ̀rù; wọn kò sì fa aṣọ wọn yá.
Mũthamaki na andũ arĩa othe maamũtungataga arĩa maiguire mohoro macio matiigana gwĩtigĩra, o na kana magĩtembũranga nguo ciao.
25 Elnatani, Delaiah àti Gemariah sì bẹ ọba kí ó má ṣe fi ìwé kíká náà jóná, ṣùgbọ́n ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn.
O na gũtuĩka Elinathani, na Delia, na Gemaria nĩmathaithire mũthamaki ndagacine ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo-rĩ, nĩaregire kũmathikĩrĩria.
26 Dípò èyí ọba pàṣẹ fún Jerahmeeli ọmọ Hameleki, Seraiah ọmọ Asrieli àti Ṣelemiah ọmọ Abdeeli láti mú Baruku akọ̀wé àti Jeremiah wòlíì ṣùgbọ́n Olúwa fi wọ́n pamọ́.
Handũ ha ũguo, mũthamaki agĩatha Jerameeli, mũrũ ũmwe wa mũthamaki, na Seraia mũrũ wa Azirieli, na Shelemia mũrũ wa Abideli, nĩguo manyiite Baruku ũcio mwandĩki, na Jeremia ũrĩa mũnabii. No rĩrĩ, Jehova nĩamahithĩte.
27 Lẹ́yìn tí ọba fi ìwé kíká náà tí ọ̀rọ̀ tí Baruku kọ láti ẹnu Jeremiah jóná tán, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá:
Thuutha wa mũthamaki gũcina ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo rĩrĩa rĩandĩkĩtwo mohoro nĩ Baruku ta ũrĩa eerĩtwo nĩ Jeremia andĩke-rĩ, ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩrĩire Jeremia, akĩĩrwo atĩrĩ:
28 “Wí pé, tún mú ìwé kíká mìíràn kí o sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé kíká èkínní tí Jehoiakimu ọba Juda fi jóná.
“Oya ibuku rĩngĩ rĩa gĩkũnjo wandĩke thĩinĩ warĩo mohoro marĩa mothe maarĩ ibuku-nĩ rĩu rĩa mbere, rĩu Jehoiakimu mũthamaki wa Juda aacinire.
29 Kí o sì wí fún Jehoiakimu ọba Juda pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí, ìwọ ti fi ìwé kíká náà jóná, o sì wí pé, “Èéṣe tí ìwọ fi kọ̀wé sínú rẹ̀, pé lóòtítọ́ ni ọba Babeli yóò wá, yóò sì pa ilẹ̀ run, àti ènìyàn, àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀.”
Ningĩ wĩre Jehoiakimu mũthamaki wa Juda atĩrĩ, ‘Jehova ekuuga atĩrĩ: Nĩwacinire ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo, ũkĩũria atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte wandĩke atĩ, ti-itherũ mũthamaki wa Babuloni nĩagooka kwananga bũrũri ũyũ na eherie andũ na nyamũ kuo?”
30 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa wí ní ti Jehoiakimu ọba Juda pé, Òun kì yóò ní ẹni tí yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, à ó sì sọ òkú rẹ̀ nù fún ooru ní ọ̀sán àti fún òtútù ní òru.
Nĩ ũndũ ũcio, Jehova ekuuga atĩrĩ ũndũ ũkoniĩ Jehoiakimu mũthamaki wa Juda: Ndakagĩa na mũndũ wa gũikarĩra gĩtĩ kĩa ũnene kĩa Daudi; kĩimba gĩake gĩgaateeo, na kĩanĩkĩrwo riũa mũthenya, na kĩhĩe nĩ mbaa ũtukũ.
31 Èmi ó sì jẹ òun àti irú-ọmọ rẹ̀, ìránṣẹ́ rẹ̀ ní ìyà nítorí àìṣedéédéé wọn; èmi ó sì mú gbogbo ibi tí èmi ti sọ sí wọn wá sórí wọn, àti sórí àwọn olùgbé Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn Juda, nítorí tí wọn kò fetísí mi.’”
Nĩngamũherithia we hamwe na ciana ciake, na arĩa mamũtungataga, nĩ ũndũ wa waganu wao; nĩngarehithĩria arĩa othe matũũraga Jerusalemu na andũ a Juda mwanangĩko ũrĩa wothe ndaaririe ũhoro waguo ũmakoniĩ, tondũ nĩmagĩte gũthikĩrĩria.’”
32 Nígbà náà ni Jeremiah mú ìwé kíká mìíràn fún Baruku akọ̀wé ọmọ Neriah, ẹni tí ó kọ̀wé sínú rẹ̀ láti ẹnu Jeremiah gbogbo ọ̀rọ̀ inú ìwé tí Jehoiakimu ọba Juda ti sun níná. A sì fi onírúurú ọ̀rọ̀ bí irú èyí kún pẹ̀lú.
Nĩ ũndũ ũcio Jeremia akĩoya ibuku rĩngĩ rĩa gĩkũnjo, akĩrĩnengera Baruku mũrũ wa Neria ũcio mwandĩki, nake akĩandĩka ibuku-inĩ rĩu mohoro mothe marĩa aacookire kũheo nĩ Jeremia, o macio maandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩrĩa Jehoiakimu mũthamaki wa Juda aacinĩte na mwaki; na hakĩongererwo mohoro mangĩ maingĩ maahaanaine na macio ma mbere.

< Jeremiah 36 >