< Jeremiah 36 >

1 Ní ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wí pé:
Judah siangpahrang Josiah capa Jehoiakim angraenghaih saning palito naah, Jeremiah khaeah Angraeng ih lok hae tiah angzoh,
2 “Mú ìwé kíká fún ará rẹ, kí o sì kọ sínú rẹ̀ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ nípa Israẹli àti ti Juda, àti sí gbogbo orílẹ̀-èdè láti ìgbà tí mo ti sọ fún ọ láti ọjọ́ Josiah títí di òní.
caqam tangoeng to la ah loe, Josiah angraenghaih saning ah lok kang thuih ni hoi kamtong vaihni ni khoek to Israel prae, Judah prae hoi prae kaminawk boih khaeah ka thuih ih misa ah ohhaih loknawk to tarik boih ah.
3 Ó lè jẹ́ wí pé ilé Juda yóò gbọ́ gbogbo ibi tí mo ti pinnu láti ṣe fún wọn; kí wọn kí ó sì yípadà, olúkúlùkù wọn kúrò ní ọ̀nà búburú rẹ̀. Kí èmi kí ó lè dárí àìṣedéédéé àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n.”
Nihcae nuiah ka phaksak han, tiah ka thuih ih amrohaih lok to Judah imthung takoh mah thaih naah, a sak o pazae ih hmuenawk to ka tahmen pae thai hanah, a caeh o ih kahoih ai loklam hoiah amlaem o khoe doeh om tih, tiah thuih.
4 Nígbà náà ni Jeremiah pe Baruku ọmọ Neriah, ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí Ọlọ́run bá a sọ fún, Baruku sì kọ láti ẹnu Jeremiah, gbogbo ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó ti sọ fún un sórí ìwé kíká náà.
To pongah Jeremiah mah, Neriah capa Baruk to kawk moe, Angraeng khae hoi angzo Jeremiah mah thuih ih loknawk boih to, Baruk mah caqam tangoeng pongah tarik pae.
5 Nígbà náà ni Jeremiah wí fún Baruku pé, “A sé mi mọ́! Èmi kò lè lọ sí ilé Olúwa.
To pacoengah Jeremiah mah, Baruk khaeah, Toksah kaminawk mah kai ang pakaa o khoep pongah, Angraeng im thungah ka caeh thai mak ai:
6 Nítorí náà, ìwọ lọ sí ilé Olúwa ní ọjọ́ àwẹ̀, kí o sì kà nínú ìwé kíká náà ọ̀rọ̀ Olúwa tí ìwọ ti ẹnu mi kọ; ìwọ ó sì kà á ní etí gbogbo Juda, tí wọ́n jáde wá láti ìlú wọn.
to pongah buhzahhaih niah, Angraeng im ah caeh ah loe Angraeng khae hoi kangzo, caqam tangoeng pongah na tarik ih ka thuih ih loknawk to kaminawk khaeah kroek paeh; angmacae vangpui hoi angzo Judah kaminawk boih khaeah doeh kroek paeh.
7 Ó lè jẹ́ pé, ẹ̀bẹ̀ wọn yóò wá sí iwájú Olúwa, wọ́n ó sì yípadà kúrò ní ọ̀nà búburú wọn; nítorí pé títóbi ni ìbínú àti ìrunú tí Olúwa ti sọ sí àwọn ènìyàn yìí.”
To tih nahaeloe nihcae mah a caeh o haih kahoih ai loklam hoiah amlaem o ueloe, Angraeng khaeah lawkthuih hoiah tahmenhaih hni o khoe doeh om tih; Angraeng palungphuihaih, kanung parai palungphuihaih hoi thuih ih hae kaminawk misa haih lok loe len parai, tiah a naa.
8 Baruku ọmọ Neriah sì ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí wòlíì Jeremiah sọ fún, láti ka ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé ní ilé Olúwa.
Tahmaa Jeremiah mah thuih ih loknawk boih, Neriah capa Baruk mah sak pae, Angraeng im thungah cabu thung ih Angraeng ih loknawk to a kroek pae.
9 Ní oṣù kẹsànán ọdún karùn-ún Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda ni wọ́n kéde àwẹ̀ níwájú Olúwa fún gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu àti fún gbogbo àwọn ènìyàn tí ó wá láti ìlú Juda.
Judah siangpahrang Josiah capa Jehoiakim angraenghaih saning pangato haih, khrah takawtto naah, Jerusalem ih kaminawk boih, Judah vangpui taeng hoi Jerusalem ah angzo kaminawk boih khaeah, Angraeng hmaa ah buhzahhaih atue to taphong o.
10 Láti inú yàrá Gemariah ọmọ Ṣafani akọ̀wé, ní àgbàlá òkè níbi ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tuntun. Baruku sì ka ọ̀rọ̀ Jeremiah láti inú ìwé ní ilé Olúwa sí etí gbogbo ènìyàn.
To naah Baruk mah, ca tarik kami Shaphan capa Gemariah ohhaih imkhaan, ranui bang ih longhma, Angraeng imthung khongkha kangtha akunhaih ahmuen ah, cabu thungah kaom Jeremiah mah thuih ih loknawk to Angraeng im ah angzo kaminawk boih khaeah kroek pae.
11 Nígbà tí Mikaiah ọmọ Gemariah ọmọ Ṣafani gbọ́ gbogbo àkọsílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé náà;
Cabu thung kaom Angraeng ih loknawk boih Shaphan capa Gemariah, Gemariah capa Mikaiah mah thaih naah,
12 Ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé ọba sínú yàrá akọ̀wé; níbi tí gbogbo àwọn ìjòyè gbé jókòó sí: Eliṣama akọ̀wé, Delaiah ọmọ Ṣemaiah, Elnatani ọmọ Akbori, Gemariah ọmọ Ṣafani àti Sedekiah ọmọ Hananiah àti gbogbo àwọn ìjòyè.
siangpahrang im thung ih ca tarik kami imkhaan ah caeh tathuk; khenah, toksah kaminawk boih, ca tarik kami Elishama, Shemiah capa Delailah, Akbor capa Elnathan, Shaphan capa Gemariah, Hananiah capa Zedekiah hoi ukkung angraengnawk boih to ahmuen ah anghnut o.
13 Lẹ́yìn tí Mikaiah sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì tí o ti gbọ́ fún wọn, nígbà tí Baruku kà láti inú ìwé kíkà náà ní etí àwọn ènìyàn.
Baruk mah kaminawk hanah cabu to kroek pae naah, Mikaiah mah a thaih ih loknawk boih to nihcae khaeah thuih pae.
14 Gbogbo àwọn ìjòyè sì rán Jehudu ọmọ Netaniah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Kuṣi sí Baruku wí pé, mú ìwé kíká náà ní ọwọ́ rẹ láti inú èyí tí ìwọ kà ní etí àwọn ènìyàn; kí o si wá. Nígbà náà ni Baruku ọmọ Neriah wá sí ọ̀dọ̀ wọn pẹ̀lú ìwé kíká ní ọwọ́ rẹ̀.
To pacoengah toksah angraengnawk boih mah, Kushi capa Shelemiah, anih ih capa Nethaniah, anih ih capa Jehudi to Baruk khaeah patoeh moe, Kaminawk khaeah na kroek pae ih caqam tangoeng to sinh moe, nihcae khaeah caeh hanah a thuisak. To pongah Neriah capa Baruk loe caqam tangoeng to ban ah sinh moe, nihcae khaeah caeh.
15 Wọ́n sì wí fún pé, “Jókòó, jọ̀wọ́ kà á sí etí wa!” Nígbà náà ni Baruku sì kà á ní etí wọn.
Toksah angraengnawk mah Baruk khaeah, Anghnu ah loe, kaicae han na kroek paeh, tiah a naa o. To pongah Baruk mah nihcae khaeah kroek pae.
16 Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ náà tan; wọ́n ń wo ara wọn lójú pẹ̀lú ẹ̀rù. Wọ́n sì wí fún Baruku pé, “Àwa gbọdọ̀ jábọ̀ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún ọba.”
To loknawk boih a thaih o naah, maeto hoi maeto zithaih palungthin tawnh o moe, Baruk khaeah hae loknawk hae siangpahrang khaeah ka thuih pae o boih han, tiah a naa o.
17 Wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ Baruku pé, “Sọ fún wa báwo ni o ṣe kọ gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí? Ṣé Jeremiah ló sọ wọ́n?”
Nihcae mah Baruk khaeah, Hae loknawk boih tarik hanah mi mah maw ang thuih? Thui ah, tiah a naa o.
18 Baruku sì dá wọn lóhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, láti ẹnu rẹ̀ ni, ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ báyìí fún mi, èmi sì fi tàdáwà kọ wọ́n sínú ìwé náà.”
Baruk mah, Jeremiah mah hae loknawk boih hae ang thuih, kaimah catui hoi cabu thungah ka tarik, tiah a naa.
19 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè sọ fún Baruku wí pé, “Lọ fi ara rẹ pamọ́ àti Jeremiah, má sì ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ibi tí ẹ̀yin wà.”
To naah toksah angraengnawk mah Baruk khaeah, Jeremiah hoi caeh hoih loe anghawk hoi ah; naa ah maw na oh hoi, tito mi mah doeh panoek hmah nasoe, tiah a naa o.
20 Lẹ́yìn tí wọ́n fi ìwé kíká náà pamọ́ sí iyàrá Eliṣama akọ̀wé, wọ́n sì wọlé tọ ọba lọ nínú àgbàlá, wọ́n sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà ní etí ọba.
Caqam tangoeng to ca tarikkung Elishama imkhaan thungah suek o pacoengah, imthung longhma ah siangpahrang khaeah caeh o moe, lok a thuih pae o boih.
21 Ọba sì rán Jehudu láti lọ mú ìwé kíká náà wá, Jehudu sì mu jáde láti inú iyàrá Eliṣama akọ̀wé. Ó sì ka ìwé náà ní etí ọba àti ní etí gbogbo àwọn ìjòyè tí ó dúró ti ọba.
To caqam tangoeng to lak hanah, siangpahrang mah Jehudi to patoeh; anih mah ca tarikkung Elishama imthung hoiah caqam tangoeng to lak. Jehudi mah siangpahrang hoi a taengah angdoe toksah angraengnawk boih hmaa ah kroek pae.
22 Ó sì jẹ́ ìgbà òtútù nínú oṣù kẹsànán, ọba sì jókòó ní ẹ̀bá iná ààrò, iná náà sì ń jó ní iwájú rẹ̀.
Hae hmuen loe khrah takawtto naah oh, siangpahrang loe siktue naah a ohhaih im ah anghnut; a hmaa ah hmaitikhaih long laom to suek moe, hmai angawt.
23 Nígbà tí Jehudu ka ojú ìwé mẹ́ta sí mẹ́rin nínú ìwé náà, ọba fi ọ̀bẹ gé ìwé, ó sì sọ sínú iná tí ó wà nínú ìdáná, títí tí gbogbo ìwé kíká náà fi jóná tán.
Jehudi mah caphaek thumto maw, palito maw kroek pacoeng kruek, caqam to haita hoiah aah moe, hmai laom thungah a vah; to tiah caqam tangoeng to hmai mah kang boih.
24 Síbẹ̀, ọba àti gbogbo àwọn ẹ̀mẹwà rẹ̀ tí wọ́n gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí kò bẹ̀rù; wọn kò sì fa aṣọ wọn yá.
Hae lok kathaih siangpahrang hoi anih ih tamnanawk thung ih kami mi kawbaktih mah doeh to lok to zii o ai; angmacae ih khukbuen doeh asik o ai.
25 Elnatani, Delaiah àti Gemariah sì bẹ ọba kí ó má ṣe fi ìwé kíká náà jóná, ṣùgbọ́n ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn.
Elnathan, Delailah hoi Gemariah cae mah caqam tangoeng hmai thlaek han ai ah siangpahrang khaeah hnik o; toe nihcae ih lok to tahngai pae ai.
26 Dípò èyí ọba pàṣẹ fún Jerahmeeli ọmọ Hameleki, Seraiah ọmọ Asrieli àti Ṣelemiah ọmọ Abdeeli láti mú Baruku akọ̀wé àti Jeremiah wòlíì ṣùgbọ́n Olúwa fi wọ́n pamọ́.
Siangpahrang mah, ca tarikkung Baruk hoi Jeremiah to naeh hanah siangpahrang capa Jerameel, Azriel capa Seraiah hoi Abdeel capa Shelemaiah to patoeh; toe Angraeng mah nihnik to hawk ving.
27 Lẹ́yìn tí ọba fi ìwé kíká náà tí ọ̀rọ̀ tí Baruku kọ láti ẹnu Jeremiah jóná tán, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá:
Jeremiah mah thuih ih loknawk baktih toengah Baruk mah tarik ih caqam tangoeng to siangpahrang mah hmai thlaek pacoengah, Angraeng ih lok Jeremiah khaeah angzoh,
28 “Wí pé, tún mú ìwé kíká mìíràn kí o sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé kíká èkínní tí Jehoiakimu ọba Juda fi jóná.
kalah caqam to la ah loe, Judah siangpahrang Jehoiakim mah hmai hoi thaek ih kangquem caqam pong ih loknawk to tarik let ah.
29 Kí o sì wí fún Jehoiakimu ọba Juda pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí, ìwọ ti fi ìwé kíká náà jóná, o sì wí pé, “Èéṣe tí ìwọ fi kọ̀wé sínú rẹ̀, pé lóòtítọ́ ni ọba Babeli yóò wá, yóò sì pa ilẹ̀ run, àti ènìyàn, àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀.”
Judah siangpahrang Jehoiakim khaeah, Angraeng mah, tipongah Babylon siangpahrang to angzo ueloe, hae prae hae phrae tih, hae ah kaom kami hoi moinawk to paduek boih tih, tiah na thuih moe, caqam tangoeng to hmai hoiah nathlaek loe? tiah thuih, tiah thui paeh, tiah ang naa.
30 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa wí ní ti Jehoiakimu ọba Juda pé, Òun kì yóò ní ẹni tí yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, à ó sì sọ òkú rẹ̀ nù fún ooru ní ọ̀sán àti fún òtútù ní òru.
To pongah Judah siangpahrang Jehoiakim kawng pongah Angraeng mah, Anih ih acaeng loe mi doeh David ih angraeng tangkhang pongah anghnu mak ai; anih ih qok loe khodai naah ni kana thungah va o ueloe, khoving naah dantui thungah va o sut tih.
31 Èmi ó sì jẹ òun àti irú-ọmọ rẹ̀, ìránṣẹ́ rẹ̀ ní ìyà nítorí àìṣedéédéé wọn; èmi ó sì mú gbogbo ibi tí èmi ti sọ sí wọn wá sórí wọn, àti sórí àwọn olùgbé Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn Juda, nítorí tí wọn kò fetísí mi.’”
Angmah hoi a caanawk, a im ah kaom kaminawk boih, angmacae sakpazaehaih pongah ka thuitaek han; nihcae loe lok tahngai o ai pongah, nihcae nuiah phaksak han ka thuih ih raihaihnawk to Jerusalem ah kaom kaminawk hoi Judah kaminawk boih nuiah ka phaksak boih han, tiah thuih, tiah a naa.
32 Nígbà náà ni Jeremiah mú ìwé kíká mìíràn fún Baruku akọ̀wé ọmọ Neriah, ẹni tí ó kọ̀wé sínú rẹ̀ láti ẹnu Jeremiah gbogbo ọ̀rọ̀ inú ìwé tí Jehoiakimu ọba Juda ti sun níná. A sì fi onírúurú ọ̀rọ̀ bí irú èyí kún pẹ̀lú.
To pongah Jeremiah mah caqam kalah to lak moe, ca tarikkung Neriah capa Baruk khaeah paek; Judah siangpahrang Jehoiakim mah hmai hoi thlaek ih caqam tangoeng thung ih loknawk boih to Jeremiah mah thuih moe, Baruk mah tarik let; to lok hoi anghmong kalah pop parai loknawk doeh tarik hoi thap.

< Jeremiah 36 >