< Jeremiah 33 >

1 Nígbà tí Jeremiah wà nínú àgbàlá túbú, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ọ́ wá lẹ́ẹ̀kejì:
Hagi Jeremaia'ma kini ne'mofo kumapima sondia vahe'ma nemanifima, kinama huno mani'nefi mani'negeno, ete nampa 2 zupa Ra Anumzamo asami'nea naneke.
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ẹni tí ó dá ayé, Olúwa tí ó mọ ayé tí ó sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, Olúwa ni orúkọ rẹ̀:
Ra Anumzama mopama tro huteno, antegeno noma'arema me fatgo hu'nea Anumzanku'ma agi'a Ra Anumzanema hu'za nehaza Ra Anumzamo'a amanage nehie,
3 ‘Pè mí, èmi ó sì dá ọ lóhùn, èmi ó sì sọ ohun alágbára ńlá àti ọ̀pọ̀ ohun tí kò ṣe é wádìí tí ìwọ kò mọ̀ fún ọ.’
Kagra nantahigege'na keka'arera Nagra ke nona hu'na ranra zantamima fra'ma ki'negenka kenka antahinka'ma osu'nana zantamina eri kaveri hanena ko.
4 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli sọ nípa àwọn ilẹ̀ ìlú yìí àti ààfin àwọn ọba Juda tí ó ti wó lulẹ̀ nítorí àwọn ìdọ̀tí àti idà
Hagi rankumapima me'nea nonteti'ene, Juda kini vahe'mokizmi nonteti'ma, tapage'ma hu'za kuma keginare'ma omente hihi hu'za mareriza mani'neza ha'ma hu'naza nontaminkura, Ra Anumzana Israeli vahe Anumzamo'a amanage huno hu'ne.
5 nínú ìjà pẹ̀lú Kaldea: ‘Wọn yóò kún fún ọ̀pọ̀ òkú ọmọkùnrin tí èmi yóò pa nínú ìbínú àti nínú ìrunú mi. Èmi ó pa ojú mi mọ́ kúrò ní ìlú yìí nítorí gbogbo búburú wọn.
Zamagra Babiloni vahe'enema ha'ma nehu'za anara hugahaze. Ana nehanageno Nagri narimpa ahe'zamo'a teve rukru hiankna nehanige'na, Jerusalemi kumapi vahera narimpa ahezmante'na zamahe frisugeno rankumapina frisaza vahe zamavufagamo'a avitegahie. Na'ankure Jerusalemi kumapima nemaniza vahe'mo'zama nehaza havi avu'ava zamo hanige'na, navugosa rukrahe nehu'na namefi huzamigahue.
6 “‘Wò ó, èmi ó mú ọ̀já àti oògùn ìmúláradá dì í; èmi ó wo àwọn ènìyàn mi sàn. Èmi ó sì jẹ́ kí wọn ó jẹ ìgbádùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀ àlàáfíà àti òtítọ́.
Hianagi henka'a ama rankumara Nagra ete eri knare nehu'na, vahe'enena zamazeri kanamaregahue. Ana hanuge'za knare nomani'zampi muse hu'za nemanisage'za mago'enena hara eme huozamantegahaze.
7 Èmi ó mú Juda àti Israẹli kúrò nínú ìgbèkùn, èmi ó sì tún wọn kọ́ gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe wà tẹ́lẹ̀.
Hagi Israeli vahe'ene Juda vahe'enena kinafintira ete zamavare'na e'na, eme zamazeri so'e hanuge'za ko'ma mani'nazaza hu'za manigahaze.
8 Èmi ó wẹ̀ wọ́n nù kúrò nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ti ṣẹ sí mi. Èmi ó sì dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ àìṣedéédéé wọn sí mi jì wọ́n.
Hagi zamagra kumi'ma hu'naza kumi'zamia maka sese hunezamante'na, Nagri'ma ha'ma renante'naza kumi'enena maka atre'zmantegahue.
9 Nígbà náà ni ìlú yìí ó fún mi ní òkìkí, ayọ̀, ìyìn àti ọlá níwájú gbogbo orílẹ̀-èdè ayé; tí wọ́n gbọ́ gbogbo rere tí èmi ṣe fún wọn. Wọn ó sì bẹ̀rù, wọn ó wárìrì fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ oore àti àlàáfíà tí èmi pèsè fún wọn.’
Hagi ana'ma hutesuge'za maka kokankoka vahe'mo'za Jerusalemi kumate'ma maka knare'nare zama eri fore'ma hanua zamofo agenkea nentahi'za, Nagri nagine hihamuni'agura husga hugahaze. Hagi Jerusalemi kuma'mofoma maka zampima azeri knare'ma hanua zamo hanige'za, vahe'mo'za koro nehu'za zamahirahiku hugahaze.
10 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ‘Ẹ̀yin yóò wí nípa ibí yìí pé, “Ó dahoro, láìsí ènìyàn tàbí ẹran.” Síbẹ̀ ní ìlú Juda àti ní òpópónà Jerusalẹmu tí ó dahoro, láìsí ẹni tó gbé ibẹ̀; ìbá à se ènìyàn tàbí ẹran, tí yóò gbọ́ lẹ́ẹ̀kan sí.
Hagi Ra Anumzamo'a huno, Tamagra huta ama kumamo'a havizantfa higeno, magore huno vahemo'ene zagagafamo'enena omani'ne huta nehuta, Judama me'nea kuma tamimpine Jerusalemi kumapima me'nea ne'onse kantamimpina, magore huno vahe'ene zagagafanena omanitfa hu'ne huta nehaze. Hianagi henka ana kuma tamimpina vahera ete esageta zamagerura antahigahaze.
11 Ariwo ayọ̀ àti inú dídùn, ohùn ìyàwó àti ti ọkọ ìyàwó àti ohùn àwọn tí ó ru ẹbọ ọpẹ́ wọn nílé Olúwa wí pé: “‘“Yin Olúwa àwọn ọmọ-ogun, nítorí Olúwa dára, ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé.” Nítorí èmi ó dá ìkólọ ilẹ̀ náà padà sí bí o ṣe wà tẹ́lẹ̀,’ ni Olúwa wí.
Hagi musenkasema nehu'za kiza zokago'ma hanaza zamagerura nentahita, veamo'za eri hagerafinaku'ma nehu'zama hanaza zamageru'enena antahigahaze. Ana nehuta Ra Anumzamofo mono nompima muse ofama eri'za ne-e'zama zagame'ma hanazana amanage hu'za nehanageta antahigahaze. Hankavenentake Ra Anumzamofona humuse huntesanune, na'ankure Ra Anumzamo'a knare hu'neankino, avesiranteno knare avu'ava'ma hunerantea zamo'a mevava huno vugahie hu'za hugahaze. Na'ankure Nagra ete zamazeri so'ema hanuge'za ko'ma mani'naza avamente'ma manisaza zanku anara hugahaze huno Ra Anumzamo'a hu'ne.
12 “Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ‘Ní ilẹ̀ yìí tí ó ti dahoro láìsí ọkùnrin àti àwọn ẹran nínú gbogbo ìlú, kò ní sí pápá oko fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti mú àwọn ẹran ọ̀sìn wọn sinmi.
Hagi Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzamo'a huno, Menina ama mopamo'ene maka ranra kuma tamimo'enena havizantfa higeno, magore huno vahemo'ene zagagafamo'enena omanitfa hu'ne. Hianagi henka vahera enemanisage'za, sipisipi kva vahe'mo'zanena sipisipi afu zagazmia zamavare'za knare trazama me'nesirega vanage'za ome mani fru hugahaze.
13 Ní ìlú òkè wọ̀n-ọn-nì, nínú ìlú àfonífojì, àti nínú ìlú ìhà gúúsù, àti ní ilẹ̀ ti Benjamini, ní ibi wọ̀n-ọn-nì tí ó yí Jerusalẹmu ká, àti ní ìlú Juda ni agbo àgùntàn yóò tún máa kọjá ní ọwọ́ ẹni tí ń kà wọ́n,’ ni Olúwa wí.
Hagi ne'onse agona kokampima me'nea kuma tamimpine, Sefela agupo mopafima me'nea kuma tamimpine, Negevi mopafima me'nea kuma tamimpine, Benzameni naga mopafima me'nea kuma tamimpine, Jerusalemi kuma tava'onte'ma me'nea mopafine, maka Juda mopafima me'nea kuma tamimpinema manisaza vahe'mo'za, ko'ma nehazaza hu'za ete sipisipi afu'zamia hampari'za erinte fatgo hugahaze. Nagra Ra Anumzamo'na ama ana nanekea nehue.
14 “‘Àwọn ọjọ́ náà ń bọ̀,’ ni Olúwa wí, ‘tí èmi ó mú ìlérí rere tí mo ṣe fún ilé Israẹli àti ilé Juda ṣẹ.
Hagi Ra Anumzamo'a huno, Mago kna ne-eankino ana knama esanige'na, Israeli vahe'ene Juda vahe'enema knare'zanku'ma huvempama huzmante'noa nanekea eri knare hugahue.
15 “‘Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àti ní àkókò náà, Èmi ó gbé olódodo dìde láti ẹ̀ka Dafidi. Yóò ṣe ìdájọ́ àti ohun tí ó tọ́ ní ilẹ̀ náà.
Hagi ana knafina zafareti kasefa azankuna rehakarufeno mareriaza hu'na, Deviti nagapinti magora fatgo avu'ava'ene ne' azeri oti'nena maka ama mopafi vahera fatgo avu'avateti refko huzmantegahie.
16 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Juda yóò di ẹni ìgbàlà. Jerusalẹmu yóò sì máa gbé láìséwu. Orúkọ yìí ni a ó máa pè é Olúwa wa olódodo.’
Hagi ana knafina Juda vahe'mokizmi zamagu nevazisageno, Jerusalemi kumapi vahe'mo'za knazana omanesige'za knare hu'za manigahaze. Ana nehu'za Jerusalemi kumakura hu'za, Ra Anumzamo'a tagri fatgo avu'avazane hu'za agia antemigahaze.
17 Nítorí báyìí ni Olúwa wí: ‘Dafidi kò ní kùnà láti rí ọkùnrin tí yóò jókòó lórí ìtẹ́ ní ilé Israẹli.
Na'ankure Ra Anumzamo'a huno, Deviti nagapintike Israeli vahe kinia mani vava hu'za nevanageno,
18 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà tí ó jẹ́ ọmọ Lefi kò ní kùnà láti ní ọkùnrin kan tí ó dúró níwájú mi ní gbogbo ìgbà láti rú ẹbọ sísun; ẹbọ jíjẹ àti láti pèsè ìrúbọ.’”
Livae nagapintike pristi vahera fore hu'za nevu'za, Nagri navurera tevefi kre fanane hu ofane, witi ofane, mago'a ofanena huvava hu'za vugahaze.
19 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá wí pé:
Hagi Ra Anumzamo'a Jeremaiana amanage huno asami'ne,
20 “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ: ‘Tí ìwọ bá lè dá májẹ̀mú mi ní òru tó bẹ́ẹ̀ tí ọ̀sán àti òru kò lè sí ní àkókò wọn mọ́.
Nagrama masane haninemoke'ma eforema huterema hana'a knama ante'noa kna mago vahe'mo'a eri atresigeno, ru knarera eforera osugaha'e.
21 Nígbà náà ni májẹ̀mú mi pẹ̀lú Dafidi ìránṣẹ́ mi àti májẹ̀mú mi pẹ̀lú Lefi tí ó jẹ́ àlùfáà, àwọn ìránṣẹ́ níwájú mi lè bàjẹ́, tí Dafidi kò sì rí ẹni láti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀.
E'i ana kanteke Nagrama huhagerafi huvempa kema hu'na, eri'za vaheni'a Deviti nagapintike kinia mani'za nevanageno, Livae nagapintike pristi vahera mani'za nevu'za Nagri eri'zana erigahazema hu'na huvempama hu'noa nanekea mago vahe'mo'a eri otregahie.
22 Èmi ó mú àwọn ọmọ lẹ́yìn Dafidi ìránṣẹ́ mi àti Lefi tí ó jẹ́ oníwàásù níwájú mi di bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, tí kò ṣe é kà àti bí iyẹ̀pẹ̀ ojú Òkun tí kò ṣe é wọ́n.’”
Hagi Nagri eri'za ne' Deviti naga'ene, eri'za vaheni'a Livae naga'enena rama'a vahe zamazeri fore ha'nena, monafi hanafi kna nehu'za hageri anke'nafi kahepankna nehanage'za vahe'mo'za ohamprigahaze.
23 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé:
Hagi Ra Anumzamo'a Jeremaiana asamino,
24 “Ǹjẹ́ ìwọ kò kíyèsi pé àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń sọ pé: ‘Olúwa ti kọ àwọn ọba méjèèjì tí ó yàn sílẹ̀’? Nítorí náà, ni wọ́n ti ṣe kẹ́gàn àwọn ènìyàn mi. Wọn kò sì mọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè kan.
Vahe'mo'zama hu'za, tare naga nofi'ma Israeli vahe'ene Juda vahe'enena, Ra Anumzamo'ma Nagri vaherema huno nehia vahe'ma amefi hunezamie hu'za vahe'mo'zama nehazana kagra nontahimpi? Anage hu'za Nagri vahera kezamasu'za zamazeri fenkami netre'za, Israeli vahera zamage amneza nesaze.
25 Báyìí ni Olúwa wí: ‘Bí èmi kò bá ti da májẹ̀mú mi pẹ̀lú ọ̀sán àti òru àti pẹ̀lú òfin ọ̀run àti ayé tí kò lè yẹ̀.
Nagrama masane haninemoke'ma me'nekema efore'ma huterema hana'a kasegene monane mopa'nemokema kankamuznire'ma me fatgoma hana'a kasegema huhagerafi'noana mago vahe'mo'a eri otregahie.
26 Nígbà náà ni èmi ó kọ ọmọ lẹ́yìn Jakọbu àti Dafidi ìránṣẹ́ mi tí èmi kò sì ní yan ọ̀kan nínú ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ́ alákòóso lórí àwọn ọmọ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu; nítorí èmi ó mú ìkólọ wọn padà; èmi ó sì ṣàánú fún wọn.’”
E'i ana kante, Jekopu naga'ene Nagri eri'za ne' Deviti nagara namefira huozamigahue. Nagra Deviti nagapinti kinia zamazeri otitere hanuge'za, Abrahamune, Aisakine, Jekopumpinti'ma forehu anante nante'ma hu'za esaza vahera, kinia mani'za kegava huzmantegahaze. Ana nehanage'na Nagra nasunku hunezamante'na kinafintira ete zamavare'na mopazmire esuge'za emani'neza maka zampina knare hu'za manigahaze.

< Jeremiah 33 >