< Jeremiah 3 >

1 “Bí ọkùnrin kan bá sì kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀ tí obìnrin náà sì lọ fẹ́ ọkọ mìíràn, ǹjẹ́ ọkùnrin náà tún lè tọ̀ ọ́ wá? Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà kò ní di aláìmọ́ bí? Ṣùgbọ́n ìwọ ti gbé pẹ̀lú onírúurú panṣágà gẹ́gẹ́ bí olùfẹ́, ṣé ìwọ yóò tún padà sọ́dọ̀ mi bí?” ni Olúwa wí.
LEUM GOD El fahk, “Mukul se fin sisla mutan kial, ac mutan sac som ac payuk sin sie pac mukul, mukul se meet ah tia ku in sifil eis mutan sac, mweyen ac tuh arulana akfohkfokyela acn uh. Tusruktu, Israel, pukanten na mwet kom pwar se, ac inge kom lungse foloko nu yuruk!
2 “Gbé ojú rẹ sókè sí ibi gíga wọ̀n-ọn-nì, kí o sì wò ó ibi kan ha wà tí a kò bà ọ́ jẹ́? Ní ojú ọ̀nà, ìwọ jókòó de àwọn olólùfẹ́, bí i ará Arabia kan nínú aginjù, ìwọ sì ti ba ilẹ̀ náà jẹ́ pẹ̀lú ìwà àgbèrè àti ìwà búburú rẹ.
Ngetak nu yen turangang fin inging uh. Ya oasr acn kom tia kukakin monum we? Kom mutana soano mwet kom pwar se pe inkanek, oana sie mwet Arab el mutana yen mwesis soano sie mwet in fahsryak elan ku in oru inkanek in sulallal nu sel. Moul in kosro lom uh akfohkfokyela acn uh.
3 Nítorí náà, a ti fa ọ̀wààrà òjò sẹ́yìn, kò sì ṣí òjò àrọ̀kúrò. Síbẹ̀ ìwọ ní ojú líle ti panṣágà, ìwọ sì kọ̀ láti ní ìtìjú.
Pa oru af uh tui, ac wangin pac af ke pacl in taknelik. Ngetnget lom an oapana ngetnget lun sie mutan kosro su eis molin kosro lal, ac kom tiana mwekin.
4 Ǹjẹ́ ìwọ kò ha a pè mí láìpẹ́ yìí pé, ‘Baba mi, ìwọ ọ̀rẹ́ mi láti ìgbà èwe mi.
“Ac inge kom fahk nu sik, ‘Kom pa papa tumuk, ac kom nuna lungsena nga e ke nga srikyak.
5 Ìwọ yóò ha máa bínú títí? Ìbínú rẹ yóò ha máa lọ títí láé?’ Báyìí ni o ṣe ń sọ̀rọ̀ ìwọ ṣe gbogbo ibi tí ìwọ le ṣe.”
Kom ac tia kasrkukrak pacl nukewa. Kom ac tia mulat sik nwe tok.’ Israel, kom fahk ouingan, a kom nuna oru na ma koluk pacl nukewa.”
6 Ní àkókò ìjọba Josiah ọba, Olúwa wí fún mi pé, “Ṣé o ti rí nǹkan tí àwọn Israẹli aláìnígbàgbọ́ ti ṣe? Wọ́n ti lọ sí àwọn òkè gíga àti sí abẹ́ àwọn igi, wọ́n sì ti ṣe àgbèrè níbẹ̀.
Ke pacl se Josiah el tuh tokosra, LEUM GOD El fahk nu sik, “Ya kom liye ma koluk Israel el oru? El forla likiyu oana sie mutan su tia pwaye nu sin mukul tumal. Fin inging nukewa ac ye sak folfol nukewa el oru oana sie mutan kosro su eis molin kosro lal.
7 Mo rò pé nígbà tí wọ́n ti ṣe èyí wọn yóò padà, wọn kò padà, Juda aláìgbàgbọ́ arábìnrin rẹ̀ náà sì rí i.
Nga tuh nunku mu tukun el oru ma inge nukewa, el ac foloko nu yuruk. Tuh pa el tiana foloko. Na Judah, tamtael se wial su tia pac pwaye nu sin mukul tumal, el liye ma inge nukewa.
8 Mo fún Israẹli aláìnígbàgbọ́ ní ìwé ìkọ̀sílẹ̀, mo sì ké wọn kúrò nítorí gbogbo àgbèrè wọn. Síbẹ̀ mo rí pé Juda tí ó jẹ́ arábìnrin rẹ̀ kò bẹ̀rù, òun náà sì jáde lọ láti lọ ṣe àgbèrè.
Judah el liye pac lah nga Israel fahsrelik, ac nga supwalla mweyen el forla likiyu ac mutawauk in sie mutan kosro su eis molin kosro lal. Tusruktu Judah, tamtael kutasrik se wial Israel, tiana sangeng. El oayapa mutawauk in moul oana sie mutan kosro,
9 Nítorí ìwà èérí Israẹli kò jọ ọ́ lójú, ó ti ba ilẹ̀ jẹ́, ó sì ti ṣe àgbèrè pẹ̀lú òkúta àti igi.
ac tia pacna mwekin kutu srisrik. El akfohkfokyela acn uh, ac orek kosro ke el alu nu ke eot ac sak.
10 Látàrí gbogbo nǹkan wọ̀nyí Juda arábìnrin rẹ̀ aláìgbàgbọ́ kò padà tọ̀ mí wá pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ̀, bí kò ṣe nípa fífarahàn bí olóòtítọ́,” ni Olúwa wí.
Tukun ma inge nukewa, Judah, tamtael kutasrik se wial Israel, el orek fwacfa mu el foloko nu yuruk, sruhk tia pwaye insial. Nga, LEUM GOD, pa fahk ma inge.”
11 Olúwa wí fún mi pé, “Israẹli aláìnígbàgbọ́ ṣe òdodo ju Juda tí ó ní ìgbàgbọ́ lọ.
Na LEUM GOD El fahk nu sik lah Israel el finne forla lukel, pwayeiya uh el wo lukel Judah, su kutasrik.
12 Lọ polongo ọ̀rọ̀ náà, lọ sí ìhà àríwá: “‘Yípadà, Israẹli aláìnígbàgbọ́,’ ni Olúwa wí. ‘Ojú mi kì yóò korò sí ọ mọ́, nítorí mo jẹ́ aláàánú, ni Olúwa wí. Èmi kì yóò sì bínú mọ́ títí láé.
El fahk nu sik in som ac fahkak kas inge nu epang, “Israel, sifilpa foloko nu yuruk, kom finne tia pwaye nu sik. Nga pakoten ac nga fah tia kasrkusrak. Nga ac fah tia sruokya mulat luk nwe tok.
13 Sá à ti mọ ẹ̀bi rẹ, ìwọ ti ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ, ìwọ ti wá ojúrere rẹ lọ́dọ̀ ọlọ́run àjèjì lábẹ́ gbogbo igikígi tí ó gbilẹ̀, ẹ̀yin kò gba ohun mi gbọ́,’” ni Olúwa wí.
Ma sefanna, kom in fahkak lah oasr ma koluk lom ke kom lain LEUM GOD lom. Fahkak lah ye sak folfol nukewa kom sang lungse lom nu sin god lun mutunfacl saya, ac lah kom tia akos ma sap luk. Nga, LEUM GOD, pa fahk ma inge.
14 “Padà, ẹ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́,” ni Olúwa wí, “nítorí èmi ni ọkọ rẹ. Èmi ó yàn ọ́, ọ̀kan láti ìlú àti méjì láti ẹ̀yà. Èmi ó sì mú ọ wá sí Sioni.
“Foloko, kowos su tia pwaye nu sik. Kowos ma luk. Nga ac eis sie suwos liki kais sie siti srisrik, ac luo suwos liki kais sie sruf, ac nga fah folokinkowosme nu Fineol Zion.
15 Lẹ́yìn èyí, èmi ó fún ọ ní àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti inú ọkàn mi, tí wọn yóò ṣáájú yín pẹ̀lú òye àti ìmọ̀.
Nga fah sot nu suwos mwet kol su akosyu, ac elos fah kol kowos ke lalmwetmet ac etauk.
16 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, tí ẹ̀yin bá pọ̀ sí i lórí ilẹ̀ náà,” ni Olúwa wí, “àwọn ènìyàn kò tún lè sọ pé, ‘Àpótí ẹ̀rí Olúwa.’ Kò ní wá sí ìrántí wọn mọ́, a kì yóò pàdánù rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni a kì yóò sì tún kan òmíràn mọ́.
Na ke kowos ac puseni in facl sac, mwet uh fah tia sifil kaskas ke Tuptup in Wuleang luk. Elos fah tia sifil nunku kac ku esam. Elos ac tia pac enenu, ku nunku in orala pac sie.
17 Ní ìgbà náà, wọn yóò pe Jerusalẹmu ní ìtẹ́ Olúwa gbogbo orílẹ̀-èdè yóò péjọ sí Jerusalẹmu láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ Olúwa, wọn kì yóò sì tún tẹ̀lé àyà líle búburú wọn mọ́.
In pacl sac, Jerusalem ac fah pangpang ‘Tron Lun LEUM GOD,’ ac mutunfacl nukewa fah tukeni we in alu nu sik. Elos fah tia sifilpa fahsr tukun inse likkeke ac koluk lalos.
18 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ni ilé Juda yóò darapọ̀ mọ́ ilé Israẹli. Wọn yóò sì wá láti ilẹ̀ àríwá wá sí ilẹ̀ tí mo fi fún àwọn baba ńlá yín gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ ìní.
Mwet Israel ac mwet Judah ac fah tukeni foloko liki sruoh lalos in acn epang, ac sifil foloko nu ke facl se nga tuh sang nu sin papa matu tomowos tuh in mwe usru lalos nwe tok.”
19 “Èmi fúnra mi sọ wí pé, “‘Báwo ni inú mi yóò ti dùn tó, kí èmi kí ó tọ́ ọ bí ọmọkùnrin kí n sì fún ọ ní ilẹ̀ tí ó tó.’ Mo rò pé ìwọ yóò pè mí ní ‘Baba mi’ o kò sì ní ṣàì tọ̀ mí lẹ́yìn.
LEUM GOD El fahk, “Israel, nga kena eis kowos oana tulik nutik Ac asot nu suwos sie facl insewowo, Su sie mwe usru wolana inmasrlon mutunfacl nukewa. Nga kena kowos in pangonyu papa, Ac tia sifil forla likiyu.
20 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí aláìgbàgbọ́ obìnrin sí ọkọ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ o jẹ́ aláìgbàgbọ́ sí mi. Ìwọ ilé Israẹli,” ni Olúwa wí.
Tusruktu kowos tiana pwaye nu sik, Oana sie mutan su tia pwaye nu sin mukul tumal. Nga, LEUM GOD, pa fahk ma inge.”
21 A gbọ́ ohùn àgàn láti ibi gíga, ẹkún àti ẹ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli, nítorí wọ́n ti yí ọ̀nà wọn po, wọ́n sì ti gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn.
Sie pusra lohngyuk yen turangang fin inging uh: Pusren tung ac kwafe lun mwet Israel Mweyen elos moulkin moul koluk, Ac mulkunla LEUM GOD lalos.
22 “Padà, ẹ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́, Èmi ó wo ìpadàsẹ́yìn kúrò ní ọ̀nà títọ́ rẹ sàn.” “Bẹ́ẹ̀, ni a ó wá sọ́dọ̀ rẹ nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run wa.
Foloko, kowos nukewa su forla liki LEUM GOD. Nga fah unwe kowos ac oru kowos in pwayena nu sik. Kowos fahk, “Aok, kut tuku nu yurum, mweyen kom LEUM GOD lasr.
23 Nítòótọ́, asán ni ìbọ̀rìṣà àti ìrúkèrúdò tí ó wà ní àwọn orí òkè kéékèèké àti àwọn òkè gíga, nítòótọ́, nínú Olúwa Ọlọ́run wa ni ìgbàlà Israẹli wà.
Wanginna kasreyasr ke kut alu nu sin god lun mwet pegan fin mangon inging uh. Kasru nu sin Israel tuku sin LEUM GOD lasr mukena.
24 Láti ìgbà èwe wa ni àwọn òrìṣà ìtìjú ti jẹ èso iṣẹ́ àwọn baba wa run, ọ̀wọ́ ẹran wọn àti agbo ẹran wọn, ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.
Tusruktu ke kut alu nu sel Baal, god lun mwekin, wanginla ma nukewa mwet matu lasr tuh kemkatu kac in pacl meet ah — un sheep ac un cow, oayapa tulik mukul ac tulik mutan.
25 Jẹ́ kí a dùbúlẹ̀ nínú ìtìjú wa, kí ìtìjú wa bò wá mọ́lẹ̀. A ti ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa, àwa àti àwọn baba wa, láti ìgbà èwe wa títí di òní a kò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa.”
Lela kut in oan in mwekin lasr, ac lela mwe mwekin lasr in afinkuti. Kut, ac mwet matu lasr, orekma koluk pacl nukewa lain LEUM GOD lasr. Kut tiana akos ma sap lal.”

< Jeremiah 3 >