< Jeremiah 27 >

1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ìṣèjọba Sedekiah ọmọ Josiah ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wí pé.
Parole du Seigneur qu'il a prononcée sur Babylone.
2 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Ṣe àjàgà àti ọ̀pá irin fún ara rẹ, kí o sì fiwé ọrùn rẹ.
Proclamez parmi les nations, faites entendre ces choses et ne les cachez pas. Dites que Babylone a succombé, que Bel a été confondu, et que Mérodach, qui vivait sans crainte et dans la mollesse, a été livré.
3 Kí o rán ọ̀rọ̀ sí ọba ti Edomu, Moabu, Ammoni, Tire àti Sidoni láti ọwọ́ àwọn ikọ̀ tí ó wá sí Jerusalẹmu sọ́dọ̀ Sedekiah ọba Juda.
Car un peuple de l'aquilon est en marche contre elle; il effacera cette contrée, depuis l'homme jusqu'à la bête, et nul ne l'habitera plus.
4 Kí o sì pàṣẹ fún wọn láti wí fún àwọn olúwa wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí: “Sọ èyí fún àwọn olúwa rẹ.
En ces jours et en ce temps-là, les fils d'Israël reviendront eux-mêmes, et avec eux, an même instant, les fils de Juda; ils marcheront pleurant et cherchant le Seigneur.
5 Pẹ̀lú agbára ńlá mi àti ọwọ́ nínà mi ni Èmi dá ayé, ènìyàn àti ẹranko tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé, mo sì fún ẹni tí ó wu ọkàn mi.
Ils interrogeront la voie pour aller à Sion; car c'est de ce côté qu'ils tourneront le visage; ils y arriveront et ils se réfugieront auprès du Seigneur Dieu; car l'alliance éternelle ne sera point mise en oubli.
6 Nísinsin yìí, Èmi yóò fa gbogbo orílẹ̀-èdè rẹ fún Nebukadnessari ọba Babeli ìránṣẹ́ mi; Èmi yóò sì mú àwọn ẹranko búburú wọ̀n-ọn-nì jẹ́ tirẹ̀.
Mon peuple est devenu un troupeau de brebis errantes; leurs pasteurs les ont dispersées; ils les ont égarées dans les montagnes; elles ont passé de colline en colline; elles ont oublié leur bergerie.
7 Gbogbo orílẹ̀-èdè ni yóò máa sìn ín àti àwọn ọmọdọ́mọ rẹ̀ títí ilẹ̀ rẹ yóò fi dé; ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè àti àwọn ọba ńlá ni yóò tẹríba fún.
Tous ceux qui les ont trouvées les ont détruites; leurs ennemis disaient: Ne les laissons pas aller, en punition de ce qu'elles ont péché contre le Seigneur. Celui qui a rassemblé leurs pères a des pâturages de justice.
8 “‘“Ṣùgbọ́n tí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan kò bá ní sin Nebukadnessari ọba Babeli, tàbí kí ó tẹ orí rẹ̀ ba ní abẹ́ àjàgà rẹ̀, Èmi yóò fi ìyà jẹ orílẹ̀-èdè náà nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, ni Olúwa wí títí Èmi yóò fi run wọ́n nípa ọwọ́ rẹ̀.
Maintenant sortez du milieu de Babylone; revenez de la terre des Chaldéens; soyez comme des dragons en face des agneaux.
9 Nítorí náà, ẹ má ṣe tẹ́tí sílẹ̀ sí àwọn wòlíì yín, àwọn aláfọ̀ṣẹ yín, àwọn tí ń rọ́ àlá fún un yín, àwọn oṣó yín, tàbí àwọn àjẹ́ yín tí wọ́n ń sọ fún un yín pé, ‘Ẹ̀yin kò ní sin ọba Babeli.’
Car voilà que je vais susciter contre Babylone les rassemblements des peuples de l'aquilon, et ils marcheront contre elle, et ils la prendront; tel le javelot d'un guerrier habile n'est jamais sans effet en revenant du combat.
10 Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ fún un yín èyí tí yóò mú u yín jìnnà réré kúrò ní ilẹ̀ yín; kí Èmi kí ó lè lé yín jáde, kí ẹ̀yin ó sì ṣègbé.
Et la Chaldée sera livrée au pillage, et tous ceux qui en prendront une part seront rassasiés;
11 Ṣùgbọ́n bí orílẹ̀-èdè kankan bá tẹ orí rẹ̀ ba lábẹ́ àjàgà ọba Babeli, tí ó sì sìn ín, Èmi yóò jẹ́ kí orílẹ̀-èdè náà wà lórí ilẹ̀ rẹ̀ láti máa ro ó, àti láti máa gbé ibẹ̀ ni Olúwa wí.”’”
Parce que vous vous êtes réjouis et glorifiés en pillant mon héritage, vous avez bondi comme des génisses dans la prairie, et vous avez frappé de vos cornes comme des taureaux.
12 Èmi sì sọ ọ̀rọ̀ náà fún Sedekiah ọba Juda wí pé: “Tẹ orí rẹ ba lábẹ́ àjàgà ọba Babeli, sìn ín ìwọ àti àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ yóò sì yè.
Votre mère a été profondément confondue; cette mère, qui vous avait enfantés au milieu des biens, a été couverte de honte; elle est la dernière des nations et désolée;
13 Kí ló dé tí ìwọ àti àwọn ènìyàn rẹ yóò ṣe kú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, èyí tí Olúwa fi ń halẹ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè tí kò bá sin ọba Babeli?
Et à cause de la colère du Seigneur elle ne sera plus habitée. Elle ne sera plus partout qu'une solitude, et quiconque traversera Babylone sera troublé, et on la sifflera en voyant ses plaies.
14 Ẹ má ṣe fetísílẹ̀ sí ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì tí ó ń sọ wí pé, ‘Ẹ̀yin kò ní sin ọba Babeli,’ nítorí pé àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fún un yín.
Investissez Babylone, vous tous qui savez tendre un arc; lancez-lui des flèches, et ne les lui épargnez pas.
15 ‘Èmi kò rán wọn ni Olúwa wí. Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké ní orúkọ mi. Nítorí náà, Èmi yóò lé wọn, wọn yóò sì ṣègbé, ẹ̀yin pẹ̀lú àwọn wòlíì tí ó ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún un yín.’”
Et prévalez sur elle; ses mains sont énervées, ses créneaux détruits, ses remparts minés. La vengeance vient de Dieu, vengez-vous d'elle; traitez-la comme elle a traité les vaincus.
16 Nígbà náà ni mo sọ fún àwọn àlùfáà àti gbogbo àwọn ènìyàn náà wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ẹ má ṣe fetí sí nǹkan tí àwọn wòlíì ń sọ pé, ‘Láìpẹ́ ohun èlò ilé Olúwa ni a ó kó padà láti Babeli,’ àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ. Ẹ má tẹ́tí sí wọn.
Exterminez la semence de Babylone et celui qui tient la faucille au temps de la moisson; en face du glaive hellénique, chacun reviendra à son peuple, et chacun se réfugiera en sa terre.
17 Má ṣe tẹ́tí sí wọn, ẹ máa sin ọba Babeli, ẹ̀yin yóò sì yè. Èéṣe tí ìlú yóò fi di ahoro?
Israël était ma brebis égarée; les lions l'avaient chassée. Le roi Assur le premier l'avait dévorée, et le roi de Babylone ensuite en avait rongé les os.
18 Tí wọ́n bá jẹ́ wòlíì, tí wọ́n sì ní ọ̀rọ̀ Olúwa, jẹ́ kí wọ́n bẹ Olúwa àwọn ọmọ-ogun kí a má ṣe kó ohun èlò tí ó kù ní ilé Olúwa àti ní ààfin ọba Juda àti Jerusalẹmu lọ sí Babeli.
À cause de cela, ainsi dit le Seigneur: Voilà que je tire vengeance du roi de Babylone, et je punis sa terre comme j'ai puni le roi Assur,
19 Nítorí pé, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ nípa àwọn opó, omi Òkun ní ti ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti ní ti ohun èlò ìyókù tí ó kù ní ìlú náà.
Et je rétablirai Israël dans son pâturage, et il reviendra paître sur le Carmel et dans les montagnes d'Éphraïm, et en Galaad, et son âme sera rassasiée.
20 Èyí tí Nebukadnessari ọba Babeli kò kó lọ nígbà tí ó mú Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babeli, pẹ̀lú àwọn ọlọ́lá Juda àti Jerusalẹmu.
En ces jours et en ces temps-là, on cherchera l'iniquité d'Israël, et il n'y en aura plus; on cherchera les péchés de Juda, et l'on n'en trouvera plus; parce que je serai propice à tous ceux qui me seront restés
21 Lóòótọ́, èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí nípa àwọn ohun ìṣúra tí ó ṣẹ́kù ní ilé Olúwa àti ní ààfin ọba Juda àti ní Jerusalẹmu:
Sur la terre, dit le Seigneur. Attaque sans merci les murs de Babylone et ceux qui l'habitent; punis-les avec le glaive; détruis-les, dit le Seigneur, et fais ce que je te commande.
22 ‘A ó mú wọn lọ sí ilẹ̀ Babeli, ní ibẹ̀ ni wọn ó sì wà títí di ìgbà tí mo bá padà,’ èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa. ‘Lẹ́yìn èyí, Èmi yóò mú wọn padà, Èmi yóò sì ṣe wọ́n lọ́jọ̀ ní ibí yìí.’”
Il y a une voix de guerre et une grande affliction en la terre des Chaldéens.
Comment a été rompu et broyé le marteau qui frappait toute la terre? Comment Babylone a-t-elle été désolée parmi les nations?
Ils te donneront l'assaut, Babylone, et tu ne sauras comment tu as été surprise. Tu as été trouvée et prise, parce que tu as résisté au Seigneur.
Le Seigneur a ouvert son trésor, et il en a tiré les instruments de sa colère; et le Seigneur Dieu a frappé la terre des Chaldéens,
Parce que leurs temps sont venus. Ouvrez ses réceptacles; fouillez-la comme une caverne; exterminez-la et qu'il ne reste rien d'elle.
Desséchez tous ses fruits, et que l'on emmène ses hommes pour les égorger. Malheur à eux; car leur jour est venu; il est venu le temps de leur rétribution.
La voix des fugitifs et de ceux qui se sont sauvés de Babylone annoncera à Sion que leur châtiment vient du Seigneur notre Dieu.
Appelez contre Babylone une multitude de guerriers, tous ceux qui tendent un arc; dressez votre camp autour de son enceinte; que nul des siens n'échappe; rétribuez-la selon ses œuvres: ce qu'elle a fait, faites-le-lui; car elle s'est élevée contre le Seigneur, contre le Dieu saint d'Israël.
À cause de cela, ses jeunes hommes tomberont dans ses places, et tous ses hommes de guerre succomberont, dit le Seigneur.
Voilà que je suis contre toi, superbe, dit le Seigneur; ton jour est venu; voilà le temps de ta rétribution,
Et ton orgueil fléchira et il sera abattu, et nul ne le relèvera; et je mettrai le feu à ta forêt, et il dévorera tout ce qui l'entoure.
Voici ce que dit le Seigneur: Tous les fils d'Israël et tous les fils de Juda ont été opprimés; tous ceux qui les ont faits captifs les ont tenus sous l'oppression; et ils n'ont point voulu les renvoyer libres;
Mais leur rédempteur est le Dieu fort; le Seigneur tout-puissant est son nom; il entrera en jugement avec ses ennemis pour délivrer la terre; et il aiguisera un glaive contre les habitants de Babylone;
Un glaive contre eux et les Chaldéens, contre tous leurs grands et tous leurs sages;
Un glaive contre tous leurs guerriers, et ils seront énervés;
Un glaive contre leurs chevaux et leurs chars, contre leurs cavaliers et le peuple mêlé parmi eux, et ils seront comme des femmes; un glaive contre leurs trésors, et ils seront dispersés;
Un glaive sur les eaux de Babylone; et les Chaldéens seront confondus, parce que leur terre est une terre d'idoles, ainsi que les îles dont ils faisaient leur orgueil.
À cause de cela, des idoles monstrueuses habiteront dans leurs îles, et les filles des sirènes dans Babylone, et elle ne sera pas repeuplée dans les siècles des siècles.
De même que Dieu a renversé Sodome et Gomorrhe et les villes voisines, dit le Seigneur, ainsi nul homme n'habitera en Babylone, et nul fils de l'homme n'y demeurera.
Voilà qu'un peuple vient de l'aquilon; et une grande nation, et nombre de rois seront suscités des extrémités de la terre,
Tenant l'arc et le glaive: ce peuple est hardi et il sera sans pitié. Leur voix retentira comme la mer; ils seront montés sur des chevaux exercés; à la guerre ils seront comme la flamme; et c'est toi qu'ils attaqueront, fille de Babylone.
Le roi de Babylone a entendu leur rumeur, et ses mains en ont été énervées, et l'angoisse l'a saisi comme les douleurs de l'enfantement.
Voilà que ce peuple va bondir comme un lion bondit du Jourdain à Étham; je détournerai promptement les miens de cette terre; je conduirai contre elle tout jeune homme: car qui est semblable à moi? Qui me résistera? Et quel est le pasteur qui se placera devant moi, face à face?
À cause de cela, écoutez le conseil que le Seigneur a décrété contre Babylone, et lu pensées qu'il a eues contre les Chaldéens qui l'habitent: Je jure que les agneaux de leurs brebis périront, et que leur pâturage sera désolé.
Car au bruit de la prise de Babylone, la terre tremblera, et une clameur sera entendue parmi les nations.

< Jeremiah 27 >