< Jeremiah 26 >

1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ìjọba ọba Jehoiakimu ọmọ Josiah tí ń ṣe ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa:
U poèetku carovanja Joakima sina Josijina cara Judina doðe ova rijeè od Gospoda govoreæi:
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí, Dúró ní àgbàlá ilé Olúwa, kí o sì sọ fún gbogbo ènìyàn ilẹ̀ Juda tí ó ti wá láti wá jọ́sìn ní ilé Olúwa, sọ fún gbogbo ohun tí mo pàṣẹ fún ọ; má ṣaláìsọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà.
Ovako govori Gospod: stani u trijemu doma Gospodnjega, i govori svijem gradovima Judinijem, koji dolaze da se poklone u domu Gospodnjem, sve rijeèi koje ti zapovijedam da im kažeš, ne izostavi ni rijeèi,
3 Bóyá gbogbo wọn máa gbọ́ ọ̀rọ̀ náà tí ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn yóò kúrò nínú ìwà búburú wọn. Èmi ó yí ọkàn padà, n kò sì ní fi ibi tí mo ti rò sí wọn ṣe wọ́n.
Ne bi li poslušali i vratili se svaki sa svoga zloga puta, da mi se sažali sa zla koje im mislim uèiniti za zloæu djela njihovijeh.
4 Sọ fún wọn wí pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Tí ẹ kò bá fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, tí ẹ kò sì gbọ́ òfin mi, ti mo gbé kalẹ̀ níwájú yín,
Reci im dakle: ovako veli Gospod: ako me ne poslušate da hodite u mom zakonu koji sam stavio pred vas,
5 àti tí ẹ kò bá gbọ́ ọ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ mi, àwọn wòlíì tí mo rán sí i yín léraléra (ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọ́),
Da slušate rijeèi sluga mojih proroka, koje vam šaljem, koje slah zarana jednako, ali ih ne poslušaste,
6 nígbà náà ni èmi yóò ṣe ilé yìí bí Ṣilo, èmi yóò sì ṣe ìlú yìí ní ìfibú sí gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.’”
Uèiniæu s domom ovijem kao sa Silomom, i grad ovaj daæu u prokletstvo svijem narodima na zemlji.
7 Àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì àti gbogbo ènìyàn ni ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Jeremiah tí ó sọ ní ilé Olúwa.
A sveštenici i proroci i sav narod èuše Jeremiju gdje govori te rijeèi u domu Gospodnjem.
8 Ṣùgbọ́n ní kété tí Jeremiah ti parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí Olúwa pàṣẹ láti sọ; àwọn àlùfáà, àti gbogbo ènìyàn dìímú, wọ́n sì wí pé, “Kíkú ni ìwọ yóò kú!
I kad Jeremija izgovori sve što mu Gospod zapovjedi da kaže svemu narodu, uhvatiše ga sveštenici i proroci i sav narod govoreæi: poginuæeš.
9 Kí ló dé tí ìwọ ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ Olúwa pé, ilé yìí yóò dàbí Ṣilo, orílẹ̀-èdè yìí yóò sì di ahoro tí kì yóò ní olùgbé.” Gbogbo àwọn ènìyàn sì kójọpọ̀ pẹ̀lú Jeremiah nínú ilé Olúwa.
Zašto prorokova u ime Gospodnje govoreæi: ovaj æe dom biti kao Silom, i ovaj æe grad opustjeti da neæe u njemu niko živjeti? I skupi se sav narod na Jeremiju u dom Gospodnji.
10 Nígbà tí àwọn aláṣẹ Juda gbọ́ nípa nǹkan wọ̀nyí, wọ́n lọ láti ààfin ọba sí ilé Olúwa, wọ́n sì mú ààyè wọn, wọ́n jókòó ní ẹnu-ọ̀nà tuntun ilé Olúwa.
A knezovi Judini èuvši to doðoše iz doma carskoga u dom Gospodnji, i sjedoše pred nova vrata Gospodnja.
11 Àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì sọ fún àwọn aláṣẹ àti gbogbo ènìyàn pé, “Arákùnrin yìí gbọdọ̀ gba ìdájọ́ ikú nítorí pé ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórí ìlú yìí: bí ẹ̀yin ti fi etí yín gbọ́!”
I rekoše sveštenici i proroci knezovima i svemu narodu govoreæi: ovaj je èovjek zaslužio smrt, jer prorokova protiv ovoga grada, kao što èuste svojim ušima.
12 Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún gbogbo àwọn aláṣẹ àti gbogbo àwọn ènìyàn wí pé: “Olúwa rán mi láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní ilé yìí àti ìlú yìí, gbogbo ohun tí ẹ ti gbọ́.
Tada progovori Jeremija svijem knezovima i svemu narodu govoreæi: Gospod me posla da prorokujem protiv ovoga doma i protiv ovoga grada sve što èuste.
13 Nísinsin yìí, tún ọ̀nà rẹ ṣe àti ìṣe rẹ, kí ẹ sì gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run yín. Olúwa yóò yí ọkàn rẹ̀ padà, kò sì ní mú ohun gbogbo tí ó ti sọ jáde ní búburú ṣẹ lórí yín.
Zato popravite putove svoje i djela svoja, i poslušajte rijeè Gospoda Boga svojega, i sažaliæe se Gospodu sa zla koje je izrekao za vas.
14 Bí ó bá ṣe tèmi ni, èmi wà ní ọwọ́ yín, ẹ ṣe ohun tí ẹ̀yin bá rò pé ó dára, tí ó sì tọ́ lójú yín fún mi.
A ja, evo sam u vašim rukama, èinite od mene što mislite da je dobro i pravo.
15 Ẹ mọ̀ dájú pé tí ẹ bá pa mí, ẹ ó mú ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ wá sórí ara yín, sórí ìlú yìí àti àwọn olùgbé inú rẹ̀; nítorí pé nítòótọ́ ni Olúwa ti rán mi láti sọ ọ̀rọ̀ yìí fún un yín.”
Ali znajte zacijelo, ako me ubijete, krv pravu svaliæete na se i na ovaj grad i na stanovnike njegove, jer doista Gospod me posla k vama da govorim sve ove rijeèi da èujete.
16 Nígbà náà ni àwọn aláṣẹ àti gbogbo àwọn ènìyàn sọ fún àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì pé, “Ẹ má ṣe pa ọkùnrin yìí nítorí ó ti bá wa sọ̀rọ̀ ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.”
Tada rekoše knezovi i sav narod sveštenicima i prorocima: nije ovaj èovjek zaslužio smrti, jer nam je govorio u ime Gospoda Boga našega.
17 Lára àwọn àgbàgbà ilẹ̀ náà sì sún síwájú, wọ́n sì sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn náà wí pé,
I ustaše neki od starješina zemaljskih, i progovoriše svemu zboru narodnom i rekoše:
18 “Mika ti Moreṣeti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní ọjọ́ Hesekiah ọba Juda. Ó sọ fún gbogbo ènìyàn Juda pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘A ó sì fa Sioni tu bí oko Jerusalẹmu yóò di òkìtì àlàpà àti òkè ilẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí ibi gíga igbó.’
Mihej Morašæanin prorokova u vrijeme Jezekije cara Judina i govori svemu narodu Judinu i reèe: ovako veli Gospod nad vojskama: Sion æe se preorati kao njiva i grad æe Jerusalim biti gomila kamenja, i gora ovoga doma visoka šuma.
19 Ǹjẹ́ Hesekiah ọba Juda tàbí ẹnikẹ́ni ní Juda pa á bí? Ǹjẹ́ Hesekiah kò bẹ̀rù Olúwa tí ó sì wá ojúrere rẹ̀? Ǹjẹ́ Olúwa kò ha a sì yí ìpinnu rẹ̀ padà, tí kò sì mú ibi tí ó ti sọtẹ́lẹ̀ yẹ̀ kúrò lórí wọn? Ibi ni a fẹ́ mú wá sórí ara wa yìí.”
Je li ga zato ubio Jezekija car Judin i sav Juda? nije li se pobojao Gospoda i molio se Gospodu? i Gospodu se sažali radi zla koje bješe izrekao na njih; mi dakle èinimo veliko zlo dušama svojim.
20 (Bákan náà Uriah ọmọ Ṣemaiah láti Kiriati-Jearimu jẹ́ ọkùnrin mìíràn tí ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ kan náà ní orúkọ Olúwa. Ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ kan náà sí ìlú náà àti ilẹ̀ yín bí Jeremiah ti ṣe.
I još bješe jedan koji prorokova u ime Gospodnje, Urija sin Semajin iz Kirijat-Jarima; on prorokova protiv ovoga grada i protiv ove zemlje isto onako kao Jeremija.
21 Nígbà tí ọba Jehoiakimu àti gbogbo àwọn aláṣẹ gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀, ọba ń wá láti pa á: ṣùgbọ́n Uriah gbọ́ èyí, ẹ̀rù bà á, ó sì sálọ sí Ejibiti.
I kad èu car Joakim i sve vojvode njegove i svi knezovi rijeèi njegove, traži ga car da ga ubije; a Urija èuvši poboja se i pobježe i doðe u Misir.
22 Ọba Jehoiakimu rán Elnatani ọmọ Akbori lọ sí Ejibiti pẹ̀lú àwọn ọkùnrin mìíràn.
A car Joakim posla neke u Misir, Elnatana sina Ahovorova i druge s njim.
23 Wọ́n sì mú Uriah láti Ejibiti lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Jehoiakimu; ẹni tí ó fi idà pa, ó sì sọ òkú rẹ̀ sí inú isà òkú àwọn ènìyàn lásán.)
I oni izvedoše Uriju iz Misira i dovedoše k caru Joakimu, i ubi ga maèem, i baci tijelo njegovo u groblje prostoga naroda.
24 Ahikamu ọmọ Ṣafani ń bẹ pẹ̀lú Jeremiah, wọn kò sì fi í lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti pa á.
Ali ruka Ahikama sina Safanova bi uz Jeremiju, te ga ne predaše u ruke narodu da ga pogube.

< Jeremiah 26 >