< Jeremiah 25 >

1 Ọ̀rọ̀ sì tọ Jeremiah wá nípa àwọn ènìyàn Juda ní ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, èyí tí ó jẹ́ ọdún kìn-ín-ní Nebukadnessari ọba Babeli.
Ko te kupu i puta mai ki a Heremaia mo te iwi katoa o Hura i te wha o nga tau o Iehoiakimi tama a Hohia kingi o Hura; ko te tau tuatahi tera o Nepukareha kingi o Papurona;
2 Nítorí náà, Jeremiah wòlíì sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti sí àwọn olùgbé Jerusalẹmu.
I korerotia taua mea e Heremaia, e te poropiti, ki te iwi katoa o Hura, ki nga tangata katoa hoki o Hiruharama; i ki ia,
3 Fún odidi ọdún mẹ́tàlélógún, bẹ̀rẹ̀ láti ọdún kẹtàlá Josiah, ọmọ Amoni ọba Juda, títí di ọjọ́ yìí, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá, mo sì ti sọ ọ́ fún un yín láti ìgbà dé ìgbà, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò fetísílẹ̀.
No te tekau ma toru o nga tau o Hohia tama a Amono kingi o Hura, a tae noa mai ki tenei ra, ka rua tekau ma toru enei nga tau, te putanga mai o te kupu a Ihowa ki ahau, me taku korero ano ki a koutou, moata ai i te ata a ka korero; heoi kihai kou tou i rongo.
4 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Olúwa ti rán gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn wòlíì sí i yín láti ìgbà dé ìgbà, ẹ̀yin kò fetísílẹ̀.
Na kua unga e Ihowa ana pononga katoa, nga poropiti ki a koutou, moata ai i nga ata a ka unga i a ratou; heoi kihai koutou i rongo, kihai ano o koutou taringa i anga ki te whakarongo;
5 Wọ́n sì wí pé, “Ẹ yípadà olúkúlùkù yín kúrò ní inú ibi rẹ̀ àti ní ọ̀nà ibi rẹ̀, ẹ̀yin yóò sì lè dúró ní ilẹ̀ tí Olúwa fún un yín àti àwọn baba yín títí láéláé.
I mea ratou, Tahuri mai koutou, e tera, e tera i tona ara kino, i te kino hoki o a koutou mahi, a e noho ki te oneone i homai e Ihowa ki a koutou ko o koutou matua, onamata a ake ake.
6 Má ṣe tọ àwọn ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn láti sìn wọ́n tàbí bọ wọ́n; ẹ má ṣe mú inú bí mi pẹ̀lú ohun tí ẹ ti fi ọwọ́ yín ṣe. Nígbà náà ni Èmi kò ní ṣe yín ní ibi.”
Kaua hoki e whaia he atua ke, kaua e mahi ki a ratou, kaua e koropiko ki a ratou, kaua hoki ahau e whakapataritaria ki te mahi a o koutou ringa; a e kore koutou e he i ahau.
7 “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò fetí sí mi,” ni Olúwa wí; “bẹ́ẹ̀ ni ẹ sì ti mú inú bí mi pẹ̀lú ohun tí ẹ fi ọwọ́ yín ṣe, ẹ sì ti mú ibi wá sórí ara yín.”
Heoi kihai koutou i rongo ki ahau, e ai ta Ihowa; he mea kia whakapataritaria ai ahau ki te mahi a o koutou ringa, hei he ano mo koutou.
8 Nítorí náà, Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ èyí: “Nítorí wí pé ẹ̀yin kò fetí sí ọ̀rọ̀ mi,
Mo reira ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano, Na kihai na koutou i rongo ki aku kupu,
9 Èmi yóò pe gbogbo àwọn ènìyàn àríwá, àti ìránṣẹ́ mi Nebukadnessari ọba Babeli,” ni Olúwa wí. “Èmi yóò sì mú wọn dìde lòdì sí ilẹ̀ náà àti àwọn olùgbé rẹ̀ àti sí gbogbo orílẹ̀-èdè àyíká rẹ̀. Èmi yóò pa wọ́n run pátápátá, Èmi yóò sọ wọ́n di nǹkan ẹ̀rù àti yẹ̀yẹ́ àti ìparun ayérayé.
Nana, ka unga tangata ahau ki te tiki i nga hapu katoa o te raki, e ai ta Ihowa, a ka unga tangata ahau ki taku pononga, ki a Nepukareha kingi o Papurona, a ka kawea mai ratou ki tenei whenua, ki ona tangata hoki, a ki nga iwi katoa nei a tawhio noa; ka tino whakangaromia ratou e ahau, ka meinga hei miharotanga, hei whakahianga atu, hei ururua tuturu.
10 Èmi yóò sì mú ìró ayọ̀ àti inú dídùn kúrò lọ́dọ̀ wọn; ohùn ìyàwó àti ọkọ ìyàwó, ìró ọlọ òkúta àti ìmọ́lẹ̀ fìtílà.
Ka tangohia atu hoki e ahau i a ratou te reo o te koa, te reo o te hari, te reo o te tane marena hou, te reo o te wahine marena hou, te haruru o nga kohatu mira, te marama hoki o te rama.
11 Gbogbo orílẹ̀-èdè yìí yóò sì di ahoro, orílẹ̀-èdè yìí yóò sì sìn ọba Babeli ní àádọ́rin ọdún.
A ka waiho tenei whenua katoa hei ururua, hei keteketenga; a ka mahi enei iwi ki te kingi o Papurona, e whitu tekau tau.
12 “Ṣùgbọ́n, nígbà tí àádọ́rin ọdún náà bá pé, Èmi yóò fi ìyà jẹ ọba Babeli àti orílẹ̀-èdè rẹ, ilẹ̀ àwọn ará Babeli nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn,” ni Olúwa wí; “bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò sọ ọ́ di ahoro títí láé.
A ka rite nga tau e whitu tekau, ka whiua e ahau te kingi o Papurona me taua iwi, e ai ta Ihowa, mo to ratou kino, me te whenua hoki o nga Karari; ka meinga a reira e ahau kia ururua a ake ake.
13 Èmi yóò sì mú gbogbo ohun tí mo ti sọ wọ̀nyí wá sórí ilẹ̀ náà, gbogbo ohun tí a ti sọ àní gbogbo èyí tí a ti kọ sínú ìwé yìí, èyí tí Jeremiah ti sọtẹ́lẹ̀ sí gbogbo orílẹ̀-èdè.
Ka kawea hoki e ahau ki runga ki taua whenua aku kupu katoa i korerotia e ahau mo reira, nga mea katoa kua oti te tuhituhi ki tenei pukapuka, kua poropititia nei e Heremaia mo aua iwi katoa.
14 Àwọn fúnra wọn yóò sì sin orílẹ̀-èdè púpọ̀ àti àwọn ọba ńlá. Èmi yóò sì sán fún oníkálùkù gẹ́gẹ́ bí ìṣe àti iṣẹ́ ọwọ́ wọn.”
Ka whakamahia hoki ratou, ae ra, ratou e nga iwi maha, e nga kingi nunui hoki: a ka rite ki a ratou hanga, ki te mahi hoki a o ratou ringa taku utu ki a ratou.
15 Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí fún mi: “Gba ago yìí ní ọwọ́ mí tí ó kún fún ọtí wáìnì ìbínú mi, kí o sì mú gbogbo orílẹ̀-èdè ti mo rán ọ sí mu ún.
Ko te kupu hoki tenei a Ihowa, a te Atua, o Iharaira ki ahau, Tangohia te kapu waina o tenei riri i toku ringa, whakainumia ma nga iwi katoa ka unga nei koe e ahau ki a ratou.
16 Nígbà tí wọ́n bá mu ún, wọn yóò ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n: bẹ́ẹ̀ ni kí wọ́n di aṣiwèrè nítorí idà tí yóò ránṣẹ́ sí àárín wọn.”
A ka inu ratou, hurori atu, hurori mai, ka haurangi, i te hoari e unga e ahau ki waenganui i a ratou.
17 Mo sì gba ago náà lọ́wọ́ Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni mo sì mú gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó rán mi sí mu ún.
Katahi ahau ka tango i te kapu i te ringa o Ihowa, whakainumia ana ma nga iwi katoa i unga nei ahau e Ihowa ki a ratou:
18 Jerusalẹmu àti àwọn ìlú Juda, àwọn ọba wọn pẹ̀lú àwọn aláṣẹ wọn, láti sọ wọ́n di ohun ìparun, ohun ẹ̀rù, ẹ̀sìn àti ègún, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti rí lónìí yìí.
Ara ma Hiruharama, ma nga pa o Hura, ma ona kingi, a ma ona rangatira, kia meinga ai ratou hei ururua, hei miharotanga, hei whakahianga, hei kanga; hei penei me to tenei ra;
19 Farao ọba Ejibiti, àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn aláṣẹ rẹ̀ àti àwọn ènìyàn rẹ̀.
Ma Parao kingi o Ihipa, ratou ko ana tangata, ko ana rangatira, ko tona iwi katoa;
20 Àti gbogbo àwọn ènìyàn àjèjì tí ó wà níbẹ̀; gbogbo àwọn ọba Usi, gbogbo àwọn ọba Filistini, gbogbo àwọn ti Aṣkeloni, Gasa, Ekroni àti gbogbo àwọn ènìyàn tí ó kù sí Aṣdodu.
Ma nga iwi i whakaranua, ma nga kingi katoa o te whenua o Uhu, ma nga kingi katoa o te whenua o nga Pirihitini, ma Ahakarono, ma Kaha, ma Ekerono, ma nga morehu ano o Aharoro:
21 Edomu, Moabu àti Ammoni;
Ma Eroma, ma Moapa, ma nga tama a Amona;
22 gbogbo àwọn ọba Tire àti Sidoni; gbogbo àwọn ọba erékùṣù wọ̀n-ọn-nì tí ń bẹ ní ìkọjá Òkun.
Ma nga kingi katoa o Taira, ma nga kingi katoa o Hairona, ma nga kingi o te motu i tera taha o te moana;
23 Dedani, Tema, Busi àti gbogbo àwọn tí ń gbé lọ́nà jíjìn réré.
Ma Rerana, ma Tema, ma Putu, ma te hunga katoa e tapahia ana nga tapa o o ratou makawe;
24 Gbogbo àwọn ọba Arabia àti àwọn ọba àwọn àjèjì ènìyàn tí ń gbé inú aginjù.
Ma nga kingi katoa o Arapia, ma nga kingi katoa o te iwi i whakaranua, e noho ana i te koraha;
25 Gbogbo àwọn ọba Simri, Elamu àti Media.
Ma nga kingi katoa o Timiri, ma nga kingi katoa o Erama, ma nga kingi katoa o nga Meri.
26 Àti gbogbo àwọn ọba àríwá ní tòsí àti lọ́nà jíjìn, ẹnìkínní lẹ́yìn ẹnìkejì; gbogbo àwọn ìjọba lórí orílẹ̀ ayé. Àti gbogbo wọn, ọba Ṣeṣaki náà yóò sì mu.
Ma nga kingi katoa o te raki, ma nga mea e tata ana, ma nga mea i tawhiti, ma tetahi, ma tetahi; ma nga kingitanga katoa hoki o te ao, i te mata o te oneone: a ka inu te kingi o Hehaka i muri i a ratou.
27 “Nígbà náà, sọ fún wọn, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli wí. Mu, kí o sì mú àmuyó kí o sì bì, bẹ́ẹ̀ ni kí o sì ṣubú láì dìde mọ́ nítorí idà tí n ó rán sí àárín yín.
Me ki ano e koe ki a ratou, Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano, a te Atua o Iharaira; E inu koutou, a haurangi iho, ruaki, e hinga ki raro, kaua e ara mai ano ki runga, i te hoari hoki e unga e ahau ki waenganui i a koutou.
28 Ṣùgbọ́n bí wọ́n ba kọ̀ láti gba ago náà ní ọwọ́ rẹ kí wọ́n sì mu ún, sọ fún wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: Ẹyin gbọdọ̀ mu ún!
Na, ki te kore ratou e pai ki te tango i te kapu i roto i tou ringa kia inumia, katahi koe ka mea ki a ratou, Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano; Me inu rawa nei e koutou.
29 Wò ó, èmi ń mú ibi bọ̀ sí orí orílẹ̀-èdè tí ó ń jẹ́ orúkọ mi; ǹjẹ́ yóò ha a lè lọ láìjìyà? Ẹ̀yin ń pe idà sọ̀kalẹ̀ sórí gbogbo àwọn olùgbé ayé, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ.’
No te mea, nana, ka timata ahau ki te whakatupu kino i te pa i huaina nei toku ingoa mo reira: a kia tukua koutou kia kahore rawa e whiua? E kore ra koutou e kore te whiua: no te mea ka karangatia e ahau he hoari ki runga ki nga tangata katoa o te whenua, e ai ta Ihowa o nga mano.
30 “Nísinsin yìí, sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí nípa wọn: “‘Kí o sì sọ pé, Olúwa yóò bú láti òkè wá, yóò sì bú kíkankíkan sí ilẹ̀ náà. Yóò parí gbogbo olùgbé ayé, bí àwọn tí ń tẹ ìfúntí.
Mo reira me poropiti e koe enei kupu katoa ki a ratou, mea atu ki a ratou, Ka hamama mai a Ihowa i te wahi tiketike, ka puaki mai tona reo i tona kainga tapu; ka tino nui tana hamama ki tana taiepa hipi; ka umere ia, ka pera i ta nga kaitakahi k arepe, ki nga tangata katoa o te whenua.
31 Ìrọ́kẹ̀kẹ̀ yóò wà títí dé òpin ilẹ̀ ayé, nítorí pé Olúwa yóò mú ìdààmú wá sí orí àwọn orílẹ̀-èdè náà, yóò mú ìdájọ́ wá sórí gbogbo ènìyàn, yóò sì fi àwọn olùṣe búburú fún idà,’” ni Olúwa wí.
Ka paku te ngangau ki te pito ra ano o te whenua; no te mea he totohe ta Ihowa ki nga iwi, ka whakawakia e ia nga kikokiko katoa; ko te hunga kino, ka tukua e ia ki te hoari, e ai ta Ihowa.
32 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Wò ó! Ibi ń tànkálẹ̀ láti orílẹ̀-èdè kan sí òmíràn; ìjì ńlá yóò sì ru sókè láti òpin ayé.”
Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano, Ka puta atu he kino i tetahi iwi ki tetahi iwi, a ka whakatututia he tukauati nui i nga pito rawa o te whenua.
33 Nígbà náà, àwọn tí Olúwa ti pa yóò wà ní ibi gbogbo, láti ìpẹ̀kun kan sí òmíràn. A kì yóò ṣọ̀fọ̀ wọn, a kì yóò kó wọn jọ tàbí sin wọ́n; ṣùgbọ́n wọn yóò dàbí ààtàn lórí ilẹ̀.
Na, ko nga tupapaku a Ihowa ka takoto i taua ra i tetahi pito o te whenua tae noa ki tetahi pito o te whenua: e kore hoki ratou e tangihia, e kore ano e kohikohia, e tanumia ranei; hei whakawairakau ratou ki te mata o te whenua.
34 Ké, kí ẹ sì pohùnréré ẹkún ẹ̀yin olùṣọ́-àgùntàn, ẹ yí nínú eruku, ẹ̀yin olùdarí agbo ẹran. Nítorí pé ọjọ́ àti pa yín ti dé, ẹ̀yin ó sì ṣubú bí ohun èlò iyebíye.
Aue, e nga hepara, hamama; okeoke i roto i te pungarehu, e nga metararahi o te kahui: kua tae mai hoki nga ra mo koutou kia patupatua, a ka tukitukia koutou e ahau mongamonga noa, a ka taka koutou ano he oko i matenuitia.
35 Àwọn olùṣọ́-àgùntàn kì yóò rí ibi sálọ kì yóò sì ṣí àsálà fún olórí agbo ẹran.
A ka kore he wahi hei rerenga mo nga hepara, kahore he mawhititanga mo nga metararahi o te kahui.
36 Gbọ́ igbe àwọn olùṣọ́-àgùntàn, àti ìpohùnréré ẹkún àwọn olórí agbo ẹran; nítorí pé Olúwa ń pa pápá oko tútù wọn run.
He reo no te tangi o nga hepara, he aue no nga metararahi o te kahui! no te mea e pahuatia ana e Ihowa to ratou haerenga hipi.
37 Ibùgbé àlàáfíà yóò di ahoro, nítorí ìbínú ńlá Olúwa.
A ka meinga kia nohopuku nga nohoanga hipi humarie; no te mea ka mura te riri o Ihowa.
38 Gẹ́gẹ́ bí kìnnìún yóò fi ibùba rẹ̀ sílẹ̀, ilẹ̀ wọn yóò sì di ahoro, nítorí idà àwọn aninilára, àti nítorí ìbínú ńlá Olúwa.
Ka whakarerea e ia tona kuhunga, ka pera i te raiona; ka waiho hoki to ratou whenua hei miharotanga i te taikaha o te hoari tukino, i te muranga o tona riri.

< Jeremiah 25 >