< Jeremiah 24 >

1 Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
Babil padixaⱨi Neboⱪadnǝsar Yerusalemdin Yǝⱨoakimning oƣli, Yǝⱨuda padixaⱨi Yǝkoniyaⱨ, Yǝⱨuda ǝmir-xaⱨzadiliri, ⱨünǝrwǝnlǝr wǝ tɵmürqilǝrni ǝsirgǝ elip Babilƣa sürgün ⱪilƣandin keyin, Pǝrwǝrdigar manga Ɵz ibadǝthanisi aldidiki ikki sewǝt ǝnjürni «mana kɵr» dǝp kɵrsǝtkǝn.
2 Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
Bir sewǝttǝ dǝslǝpki pixⱪan ǝnjürdǝk intayin yahxi ǝnjürlǝr bar idi; ikkinqi sewǝttǝ yegili bolmaydiƣan, intayin naqar ǝnjürlǝr bar idi.
3 Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?” Mo dáhùn pe, “Èso ọ̀pọ̀tọ́.” Mo dáhùn. “Èyí tí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí tí ó burú burú rékọjá tí kò sì ṣe é jẹ.”
Andin Pǝrwǝrdigar manga: «Nemǝ kɵrdüng, Yǝrǝmiya?» — dǝp soridi. Mǝn: «Ənjürlǝrni kɵrdüm; yahxiliri bolsa intayin yahxikǝn; naqarliri yegili bolmaydiƣan, intayin naqar ikǝn» — dedim.
4 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Pǝrwǝrdigarning sɵzi manga kelip mundaⱪ deyildi: —
5 “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
Israilning Hudasi bolƣan Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Mǝn Yǝⱨudadin sürgün bolƣanlarni, yǝni Mening bu yǝrdin kaldiylǝrning zeminiƣa ǝwǝtkǝnlirimni bu yahxi ǝnjürlǝrdǝk yahxi dǝp ⱪaraymǝn;
6 Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
Mǝn ularƣa yahxi bolsun dǝp kɵzümni ularƣa tikimǝn wǝ ularni bu zeminƣa ⱪayturimǝn; Mǝn ularni ƣulitip taxlimaymǝn, bǝlki ularni ⱪurimǝn; ularni yulup taxlimaymǝn, bǝlki tikip ɵstürimǝn.
7 Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
Mǝn ularƣa Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni bilidiƣan, Meni tonuydiƣan bir ⱪǝlbni tǝⱪdim ⱪilimǝn; xuning bilǝn ular Mening hǝlⱪim bolidu, Mǝn ularning Hudasi bolimǝn; qünki ular pütün ⱪǝlbi bilǝn yenimƣa ⱪaytidu.
8 “‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
Lekin naqar ǝnjürlǝr, yǝni yegili bolmaydiƣan, intayin naqar ǝnjürlǝr ⱪandaⱪ bolƣan bolsa, — dǝydu Pǝrwǝrdigar, — Bǝrⱨǝⱪ, Mǝn Yǝⱨuda padixaⱨi Zǝdǝkiyani, ǝmir-xaⱨzadilirini wǝ Yerusalemdikilǝrning ⱪalƣan ⱪismini, bu zeminda ⱪalƣanlarni wǝ Misirda turuwatⱪanlarni xuningƣa ohxax ⱪilimǝn;
9 Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
Mǝn ularni yǝr yüzidiki barliⱪ padixaⱨliⱪlarƣa wǝⱨimǝ salƣuqi bir obyekt boluxⱪa, külpǝtkǝ qüxüxkǝ tapxurimǝn; mǝn ularni ⱨǝydiwǝtkǝn barliⱪ jaylarda ularni rǝswaqiliⱪning obyekti, sɵz-qɵqǝk, tapa-tǝnining obyekti wǝ lǝnǝt sɵzliri boluxⱪa tapxurimǝn.
10 Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’”
Mǝn ularƣa ⱨǝm ata-bowiliriƣa tǝⱪdim ⱪilƣan zemindin yoⱪitilƣuqǝ ular arisiƣa ⱪiliq, ⱪǝⱨǝtqilik wǝ wabani ǝwǝtimǝn.

< Jeremiah 24 >