< Jeremiah 24 >

1 Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
Thuutha wa Jekonia mũrũ wa Jehoakimu mũthamaki wa Juda na anene ake, na mabundi na atũũri a Juda gũtahwo, makĩrutwo Jerusalemu magĩtwarwo Babuloni nĩ Nebukadinezaru, mũthamaki wa Babuloni-rĩ, Jehova nĩanyonirie ikabũ igĩrĩ cia ngũyũ ciigĩtwo hau mbere ya hekarũ ya Jehova.
2 Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
Gĩkabũ kĩmwe kĩarĩ na ngũyũ njega mũno, ta ngũyũ iria ciambaga kwĩrua; gĩkabũ kĩrĩa kĩngĩ kĩarĩ na ngũyũ njũru mũno, itangĩrĩĩka nĩ ũndũ wa ũrĩa ciathũkĩte.
3 Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?” Mo dáhùn pe, “Èso ọ̀pọ̀tọ́.” Mo dáhùn. “Èyí tí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí tí ó burú burú rékọjá tí kò sì ṣe é jẹ.”
Hĩndĩ ĩyo Jehova akĩnjũũria atĩrĩ, “Jeremia, nĩ kĩĩ ũroona?” Ngĩmũcookeria atĩrĩ, “Nĩ ngũyũ. Iria njega nĩ njega mũno, no iria njũru nĩ njũru mũno ũndũ itangĩrĩĩo.”
4 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Hĩndĩ ĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩkĩnginyĩra, ngĩĩrwo atĩrĩ:
5 “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
“Jehova, Ngai wa Isiraeli ekuuga atĩrĩ: ‘O ta ngũyũ ici imwe njega-rĩ, ũguo noguo nyonaga andũ a Juda marĩ ega arĩa maatahirwo, acio ndaarutire gũkũ ngĩmatwara bũrũri wa Babuloni.
6 Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
Maitho makwa nĩmakamarora na ndĩmeeke maũndũ mega, na nĩngamacookia gũkũ bũrũri ũyũ. Nĩngamarũgamia na ndikamamomora; nĩngamahaanda na ndigacooka kũmamunya.
7 Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
Nĩngamahe ngoro ya gũtũma mamenye atĩ nĩ niĩ Jehova. Nĩmagatuĩka andũ akwa na niĩ nduĩke Ngai wao, nĩgũkorwo nĩmakanjookerera na ngoro ciao ciothe.
8 “‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
“‘No rĩrĩ, o ta ngũyũ icio njũru, icio itangĩrĩĩka nĩ ũndũ wa ũrĩa ithũkĩte-rĩ,’ Jehova ekuuga atĩrĩ, ‘ũguo no taguo ngeeka Zedekia mũthamaki wa Juda, na anene ake o na matigari ma andũ a Jerusalemu, arĩa magaakorwo matigaire gũkũ bũrũri ũyũ kana arĩa matũũraga bũrũri wa Misiri.
9 Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
Nĩngatũma mathũũrwo mũno, matuĩke kĩndũ gĩa gũthirĩkia mothamaki mothe ma gũkũ thĩ, na mameneke na matuĩke a kuunagwo thimo, na matũũre mathekagĩrĩrwo na manyiitagwo nĩ kĩrumi kũrĩa guothe ngaamathaamĩria.
10 Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’”
Nĩngamarehithĩria rũhiũ rwa njora, na ngʼaragu, na mũthiro imokĩrĩre, nginya maniinwo mathire bũrũri-inĩ ũrĩa ndaamaheire o na ngĩhe maithe mao.’”

< Jeremiah 24 >