< Jeremiah 24 >

1 Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
Bangʼ ka Jehoyakin wuod Jehoyakim ruodh Juda kod jotelo, jopecho kod jogoro mag Juda ne oseter e twech koa Jerusalem nyaka Babulon gi Nebukadneza ruodh Babulon, Jehova Nyasaye nonyisa kikepni ariyo mag ngʼope koketi e nyim hekalu mar Jehova Nyasaye.
2 Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
Okapu achiel ne nigi ngʼope mabeyo ahinya, kod mago mane osechiek chon; okapu machielo ne nigi ngʼope maricho, marach moloyo ma ok nyal cham.
3 Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?” Mo dáhùn pe, “Èso ọ̀pọ̀tọ́.” Mo dáhùn. “Èyí tí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí tí ó burú burú rékọjá tí kò sì ṣe é jẹ.”
Eka Jehova Nyasaye nopenja niya, “En angʼo mineno, Jeremia?” Ne odwoko niya, “Aneno ngʼope. Mabeyo to beyo ahinya, to maricho to richo ahinya ma ok nyal cham.”
4 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Eka wach Jehova Nyasaye nobirona:
5 “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
“Ma e gima Jehova Nyasaye, Nyasach Israel, wacho: ‘Ka ngʼope mabeyogi, akawo jogo moa Juda kodhi e twech kaka joma beyo, mane agolo kae kadhi e piny jo-Babulon.
6 Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
Wengena nongʼigi mondo gidhi maber, kendo anadwog-gi e pinyni. Anagergi kendo ok anamukgi; anapidhgi kendo ok anapudhgi.
7 Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
Anamigi chuny mar ngʼeya ni an Jehova Nyasaye. Ginibed joga kendo anabed Nyasachgi, nimar giniduog ira gi chunygi duto.’
8 “‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
“Jehova Nyasaye wacho ni, ‘To mana kaka ngʼope maricho, ma ok nyal cham, e kaka anatimne Zedekia ruodh Juda, jotende kod jogo motony moa Jerusalem, kata obedo ni gidongʼ e pinyni kata gidak Misri.
9 Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
Abiro kelo kuomgi achaya kendo joma ok dwar gi pinjeruodhi duto manie piny, ma wangʼo ich kendo itiyo godo kaka ranyisi, gima ibwogogo ji kendo ikwongʼogo, ka moro amora ma aterogie.
10 Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’”
Anakel ligangla, kech kod masira kuomgi nyaka tiekgi e piny mane amiyogi kod wuonegi.’”

< Jeremiah 24 >