< Jeremiah 22 >
1 Báyìí ni Olúwa wí, “Sọ̀kalẹ̀ lọ sí ààfin ọba Juda, kí o sì sọ ọ̀rọ̀ yìí níbẹ̀:
Ko te kupu tenei a Ihowa; Haere ki raro, ki te whare o te kingi o Hura, ka korero i tenei kupu ki reira,
2 ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ìwọ ọba Juda, tí ó jókòó ní ìtẹ́ Dafidi, ìwọ, àwọn ènìyàn rẹ àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ, tí ó wọlé láti ẹnu ibodè wọ̀nyí.
Mea atu Whakarongo ki te kupu a Ihowa, e te kingi o Hura, e noho na i runga i te torona o Rawiri, a koe, koutou ko ou tangata, ko tou iwi e tomo ana ki enei kuwaha;
3 Báyìí ni Olúwa wí: Ṣé ohun tí ó jẹ́ òtítọ́ tí ó sì yẹ, kí o sì gba ẹni tí a fi ẹ̀tọ́ rẹ̀ dù ú kúrò lọ́wọ́ aninilára. Kí ó má ṣe fi agbára àti ìkà lé àlejò, aláìní baba, tàbí opó, ìwọ kò sì gbọdọ̀ ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ níbí yìí.
Ko te kupu tenei a Ihowa, Whakaritea te whakawa me te tika, whakaorangia te tangata e pahuatia ana i te ringa o te kaitukino: kaua e mauria kinotia, kaua e whakatupuria kinotia te manene, te pani, te pouaru, kaua hoki e whakahekea te toto harakor e ki tenei wahi.
4 Nítorí bí ẹ̀yin bá tẹ̀lé àṣẹ wọ̀nyí, nígbà náà ni àwọn ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba inú ààfin láti ẹnu-ọ̀nà, wọn yóò gun kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin, àwọn àti ìránṣẹ́ wọn àti àwọn ènìyàn wọn.
No te mea ki te mahia marietia tenei e koutou, katahi ka tomo mai ki nga kuwaha o tenei whare he kingi e noho ana i runga i te torona o Rawiri, e eke ana ki te hariata, ki te hoiho, a ia, me ana tangata, me tona iwi.
5 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá tẹ̀lé àṣẹ wọ̀nyí, mo búra fúnra mi pé ààfin yìí yóò di ìparun ni Olúwa wí.’”
Engari ki te kore koutou e whakarongo ki enei kupu, hei oati tenei maku ki ahau ano, e ai ta Ihowa, tera tenei whare e takoto kau.
6 Nítorí báyìí ni Olúwa wí, nípa ààfin ọba Juda, “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwọ dàbí Gileadi sí mi, gẹ́gẹ́ bí góńgó òkè Lebanoni, dájúdájú Èmi yóò sọ ọ́ di aṣálẹ̀, àní gẹ́gẹ́ bí ìlú tí a kò gbé inú wọn.
Ko te kupu hoki tenei a Ihowa mo te whare o te kingi o Hura, Ko Kireara koe ki ahau, a ko te tihi o Repanona; otiia he pono ka meinga koe e ahau hei koraha, hei pa hoki e kore e nohoia.
7 Èmi ó ya àwọn apanirun sọ́tọ̀ fún ọ, olúkúlùkù ọkùnrin pẹ̀lú ohun ìjà rẹ̀, wọn yóò sì gé àṣàyàn igi kedari rẹ lulẹ̀, wọn ó sì kó wọn jù sínú iná.
A ka whakaritea e ahau he kaiwhakangaro mou, rite rawa i tana patu, i tana patu: a ka tuaina e ratou ou hita papai, ka maka hoki ki te ahi.
8 “Àwọn ènìyàn láti ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò rékọjá lẹ́bàá ìlú yìí wọn yóò sì máa bi ara wọn léèrè pé, ‘Èéṣe tí Olúwa ṣe irú èyí sí ìlú ńlá yìí?’
A he maha nga iwi e haere ma te taha o tenei pa, a ka mea tena ki tona hoa, ki tona hoa, He aha tenei i meatia e Ihowa ki tenei pa nui?
9 Ìdáhùn wọn yóò sì jẹ́: ‘Nítorí tí wọ́n ti kọ májẹ̀mú Olúwa Ọlọ́run wọn sílẹ̀, wọn ti ń fi orí balẹ̀ fún ọlọ́run mìíràn, wọ́n sì sìn wọ́n.’”
Katahi ratou ka ki ake, Mo ratou i whakarere i te kawenata a Ihowa, a to ratou Atua, a koropiko ana ki nga atua ke, mahi atu ana ki a ratou.
10 Nítorí náà má ṣe sọkún nítorí ọba tí ó ti kú tàbí ṣọ̀fọ̀ fún àdánù rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ sọkún kíkorò fún ẹni tí a lé kúrò nílùú nítorí kì yóò padà wá mọ́ tàbí fi ojú rí ilẹ̀ tí a ti bí i.
Kaua koutou e tangi ki te tupapaku, e uhunga ranei ki a ia: engari kia nui te tangi mo te tangata e haere atu ana; no te mea e kore ia e hoki mai a muri, e kore ano e kite i te whenua i whanau ai ia.
11 Nítorí báyìí ni Olúwa wí, nípa Ṣallumu ọmọ Josiah ọba Juda tí ó jẹ ọba lẹ́yìn baba rẹ̀, ṣùgbọ́n tí ó jáde kúrò níhìn-ín: “Òun kì yóò padà wá mọ́.
Ko te kupu hoki tenei a Ihowa mo Harumu tama a Hohia, kingi o Hura, i kingi nei i muri i tona papa, i a Hohia, i haere atu nei hoki i tenei wahi; E kore ia e hoki mai ki konei a ake ake:
12 Yóò kú ni ibi tí a mú u ní ìgbèkùn lọ, kì yóò sì rí ilẹ̀ yìí mọ́.”
Engari hei te wahi i whakaraua atu ai ia, ka mate ia ki reira, a e kore ia e kite i tenei whenua a ake ake.
13 “Ègbé ni fún ẹni tí a kọ́ ààfin rẹ̀ lọ́nà àìṣòdodo, àti àwọn yàrá òkè rẹ̀ lọ́nà àìtọ́ tí ó mú kí àwọn ará ìlú rẹ ṣiṣẹ́ lásán láìsan owó iṣẹ́ wọn fún wọn.
Aue, te mate mo te tangata e hanga nei i tona whare ki te he, i nga ruma hoki o reira ki te whakawa he; e whakamahi nei i tona hoa, kahore e utua, kahore hoki e hoatu to tana mahi ki a ia;
14 Ó wí pé, ‘Èmi ó kọ́ ààfin ńlá fún ara mi àwọn yàrá òkè tí ó fẹ̀, ojú fèrèsé rẹ̀ yóò tóbi.’ A ó sì fi igi kedari bò ó, a ó fi ohun aláwọ̀ pupa ṣe é ní ọ̀ṣọ́.
E mea ana, Ka hanga e ahau he whare mahorahora moku, he rarahi nga ruma, pokaia ana he matapihi mona i roto; a ko te hipoki he hita, pania ake ki te whero ngangana.
15 “Ìwọ ó ha jẹ ọba kí ìwọ kí ó lè ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ igi kedari? Baba rẹ kò ha ní ohun jíjẹ àti mímu? Ó ṣe ohun tí ó tọ́ àti òdodo, nítorí náà ó dára fún un.
E kingi ranei koe, no te mea e whai ana koe kia pera rawa atu te hita? kihai ianei tou papa i kai, i inu, i whakarite i te whakawa, i te tika? a he pai i reira ki a ia.
16 Ó gbèjà òtòṣì àti aláìní, ohun gbogbo sì dára fún un. Bí a ti mọ̀ mí kọ́ ni èyí?” ni Olúwa wí.
I whakaritea e ia te whakawa a te ware, a te rawakore; a he pai i reira. He teka ianei ko te mohio tenei ki ahau? e ai ta Ihowa.
17 “Ṣùgbọ́n ojú rẹ àti ọkàn rẹ wà lára èrè àìṣòótọ́ láti ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ìnilára àti ìlọ́nilọ́wọ́gbà.”
Kahore hoki ou kanohi, ou ngakau mo tetahi mea ke atu, heoi mo tou apo anake, mo te whakaheke i te toto harakore, mo te tukino, mo te tutu, hei mahi, mau.
18 Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí, nípa Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda: “Wọn kì yóò ṣọ̀fọ̀ fún un: wí pé, ‘Ó ṣe, arákùnrin mi! Ó ṣe, arábìnrin mi!’ Wọn kì yóò ṣọ̀fọ̀ fún un: wí pé, ‘Ó ṣe, olúwa tàbí ó ṣe ọlọ́lá!’
Mo reira ko ta Ihowa kupu tenei mo Iehoiakimi tama a Hohia kingi o Hura; Kahore he tangi mona, he mea, Aue, e toku tuakana! ko tenei ranei, Aue, e te tuahine! kahore ratou e tangi mona, e mea, Aue, te ariki! Aue, tona kororia!
19 A ó sin òkú rẹ̀ bí i kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí a wọ́ sọnù láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu.”
Ka tanumia ia ki te tanu o te kaihe, ka toia, ka maka ki waho i nga kuwaha o Hiruharama.
20 “Gòkè lọ sí Lebanoni, kígbe síta, kí a sì gbọ́ ohùn rẹ ní Baṣani, kí o kígbe sókè láti Abarimu, nítorí a ti ṣẹ́ gbogbo olùfẹ́ rẹ túútúú.
E piki ki Repanona tangi ai; kia puaki hoki tou reo i Pahana: tangi mai hoki i Aparimi; kua mongamonga katoa hoki te hunga i aroha ki a koe.
21 Èmi ti kìlọ̀ fún ọ nígbà tí o rò pé kò séwu, ṣùgbọ́n o sọ pé, ‘Èmi kì yóò fetísílẹ̀!’ Èyí ni iṣẹ́ rẹ láti ìgbà èwe rẹ, ìwọ kò fìgbà kan gba ohùn mi gbọ́.
I korero ahau ki a koe i te wa o tou rangatiratanga; engari i mea koe, E kore ahau e rongo. Ko tau tikanga tenei no tou tamarikitanga ake, kihai koe i rongo ki toku reo.
22 Ẹ̀fúùfù yóò lé gbogbo àwọn olùṣọ́-àgùntàn rẹ̀ lọ, gbogbo àwọn olùfẹ́ rẹ yóò lọ sí ìgbèkùn, nígbà náà ni a ó kẹ́gàn rẹ, ojú yóò tì ọ́ nítorí gbogbo ìwà búburú rẹ.
Ma te hau e whangai au hepara katoa, ka riro hoki te hunga i aroha ki a koe ki te whakarau: katahi rawa koe ka whakama, ka numinumi kau ki tou kino katoa.
23 Ìwọ tí ń gbé ‘Lebanoni,’ tí ó tẹ́ ìtẹ́ sí orí igi kedari, ìwọ yóò ti kérora pẹ́ tó, nígbà tí ìrora bá dé bá ọ, ìrora bí i ti obìnrin tí ń rọbí!
E te wahine e noho na i Repanona, e hanga na i tou kohanga ki nga hita, ano te nui o te manawapa mou ina tae nga mamae ki a koe, te mamae e rite ana ki to te wahine e whanau ana!
24 “Dájúdájú bí èmi ti wà láààyè,” ni Olúwa wí, “Bí Koniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda tilẹ̀ jẹ́ òrùka èdìdì lọ́wọ́ ọ̀tún mi, síbẹ̀ èmi ó fà ọ́ tu kúrò níbẹ̀.
E ora ana ahau, e ai ta Ihowa, ahakoa a Konia tama a Iehoiakimi kingi o Hura, ko te mowhiti i runga i toku ringa matau, ka unuhia tonutia atu koe e ahau i reira;
25 Èmi ó sì fà ọ́ lé ọwọ́ àwọn tí ó ń wá ẹ̀mí rẹ, àwọn tí ìwọ bẹ̀rù, àní lé ọwọ́ Nebukadnessari, ọba Babeli àti ọwọ́ àwọn ará Babeli.
A ka hoatu koe e ahau ki te ringa o te hunga e whai ana kia whakamatea koe, ki te ringa ano o te hunga e wehi na koe, ara ki te ringa o Nepukareha kingi o Papurona, ki te ringa hoki o nga Karari.
26 Èmi ó fi ìwọ àti ìyá tí ó bí ọ sọ̀kò sí ilẹ̀ mìíràn, níbi tí a kò bí ẹnikẹ́ni nínú yín sí. Níbẹ̀ ni ẹ̀yin méjèèjì yóò kú sí.
Ka akiritia atu ano koe e ahau me tou whaea i whanau ai koe ki tetahi atu whenua ehara nai i te wahi i whanau ai korua; a mate atu korua ki reira.
27 Ẹ̀yin kì yóò padà sí ilẹ̀ tí ẹ̀yin fẹ́ mọ́ láéláé.”
Engari ko te whenua i okaka tonu ai o raua ngakau kia hoki ki reira, e kore raua e hoki ki reira,
28 Ǹjẹ́ Jehoiakini ẹni ẹ̀gàn yàtọ̀ sí ìkòkò òfìfo, ohun èlò tí ẹnìkan kò fẹ́? Èéṣe tí a fi òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ sókè sí ilẹ̀ tí wọn kò mọ̀.
Ko tenei tangata, ko Konia, he oko pakaru ranei ai e whakahaweatia ana? he oko kahore e matenuitia ana? he aha i akiritia atu ai, ratou ko ona uri, i maka atu ai ki te whenua kihai i mohiotia e ratou?
29 Ìwọ ilẹ̀, ilẹ̀, ilẹ̀, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa!
E te whenua, te whenua, te whenua, whakarongo ki te kupu a Ihowa.
30 Báyìí ni Olúwa wí: “Kọ àkọsílẹ̀ ọkùnrin yìí sínú ìwé gẹ́gẹ́ bí aláìlọ́mọ, ẹni tí kì yóò ṣe rere ní ọjọ́ ayé rẹ̀; nítorí ọ̀kan nínú irú-ọmọ rẹ̀ kì yóò ṣe rere, èyíkéyìí wọn kì yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi tàbí jẹ ọba ní Juda mọ́.”
Ko te kupu tenei a Ihowa, Tuhituhia e koutou tenei tangata, he urikore, he tangata e kore e oti pai tana i ona ra e ora ai: e kore hoki e totika ta tetahi o ona uri e noho ana i runga i te torona o Rawiri, e kingi ana a muri ake nei i roto i a H ura.