< Jeremiah 22 >
1 Báyìí ni Olúwa wí, “Sọ̀kalẹ̀ lọ sí ààfin ọba Juda, kí o sì sọ ọ̀rọ̀ yìí níbẹ̀:
Hina Gode da na Yuda hina bagade (Da: ibidi egaga fi) amo ea diasuga asili, hina bagade, amola ea eagene ouligisu dunu amola Yelusaleme fi dunu ilima Ea sia: amane olelema: ne sia: i,
2 ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ìwọ ọba Juda, tí ó jókòó ní ìtẹ́ Dafidi, ìwọ, àwọn ènìyàn rẹ àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ, tí ó wọlé láti ẹnu ibodè wọ̀nyí.
3 Báyìí ni Olúwa wí: Ṣé ohun tí ó jẹ́ òtítọ́ tí ó sì yẹ, kí o sì gba ẹni tí a fi ẹ̀tọ́ rẹ̀ dù ú kúrò lọ́wọ́ aninilára. Kí ó má ṣe fi agbára àti ìkà lé àlejò, aláìní baba, tàbí opó, ìwọ kò sì gbọdọ̀ ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ níbí yìí.
“Na, Hina Gode, da amane sia: sa. Moloidafa hou eso huluane hamoma: ne, ouligima! Ogogosu hamosu dunu ilia logo hedofama amola dunu ilima ilia da ogogosa, amo gaga: ma! Ga fi dunu amola guluba: mano amola didalo, ilima mae wadela: le hamoma. Amola amo hadigi moilai bai bagade ganodini, hou ida: iwane hamoi dunu, amo mae medole legema.
4 Nítorí bí ẹ̀yin bá tẹ̀lé àṣẹ wọ̀nyí, nígbà náà ni àwọn ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba inú ààfin láti ẹnu-ọ̀nà, wọn yóò gun kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin, àwọn àti ìránṣẹ́ wọn àti àwọn ènìyàn wọn.
Dilia da dafawane Na sia: i defele hamosea, amasea Da: ibidi egaga fi da hina bagade hawa: hamosu hamonanumu. Amola ilia, amola ilia eagene ouligisu dunu, da hina bagade ea diasu logo holei amoga mae yolesili, hosi amola ‘sa: liode’ da: iya fila heda: iwane golili masunu.
5 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá tẹ̀lé àṣẹ wọ̀nyí, mo búra fúnra mi pé ààfin yìí yóò di ìparun ni Olúwa wí.’”
Be dilia Na sema higale, hame nabasea, Na da dafawane ilegele sia: sa. Amo hina bagade diasu da mugululi, wadela: lesi dagoi ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
6 Nítorí báyìí ni Olúwa wí, nípa ààfin ọba Juda, “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwọ dàbí Gileadi sí mi, gẹ́gẹ́ bí góńgó òkè Lebanoni, dájúdájú Èmi yóò sọ ọ́ di aṣálẹ̀, àní gẹ́gẹ́ bí ìlú tí a kò gbé inú wọn.
Na da Yuda hina bagade diasu noga: idafa Gilia: de soge amola Lebanone Goumi defele hahawane ba: sa. Be Na da amo wadela: lesili, hafoga: i soge amo ganodini dunu da esalumu hame dawa: , amo defele hamomu.
7 Èmi ó ya àwọn apanirun sọ́tọ̀ fún ọ, olúkúlùkù ọkùnrin pẹ̀lú ohun ìjà rẹ̀, wọn yóò sì gé àṣàyàn igi kedari rẹ lulẹ̀, wọn ó sì kó wọn jù sínú iná.
Na da amo wadela: lesimusa: , dunu asunasili, ilia da goahei gaguli misini, ea noga: idafa dolo golasu ifa damuni, laluga ha: digimu.
8 “Àwọn ènìyàn láti ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò rékọjá lẹ́bàá ìlú yìí wọn yóò sì máa bi ara wọn léèrè pé, ‘Èéṣe tí Olúwa ṣe irú èyí sí ìlú ńlá yìí?’
Fa: no, ga fi dunu bagohame da amo baligimusa: ahoasea, amane sia: dalumu, ‘Hina Gode da abuliba: le amo moilai bai bagade noga: idafa wadela: lesibala: ?’
9 Ìdáhùn wọn yóò sì jẹ́: ‘Nítorí tí wọ́n ti kọ májẹ̀mú Olúwa Ọlọ́run wọn sílẹ̀, wọn ti ń fi orí balẹ̀ fún ọlọ́run mìíràn, wọ́n sì sìn wọ́n.’”
Amasea, ilisu da bu adole imunu, ‘Bai Yuda dunu da ilia Gode Ea Gousa: su yolesili, eno ogogosu ‘gode’ ilima nodoi amola hawa: hamoi.’”
10 Nítorí náà má ṣe sọkún nítorí ọba tí ó ti kú tàbí ṣọ̀fọ̀ fún àdánù rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ sọkún kíkorò fún ẹni tí a lé kúrò nílùú nítorí kì yóò padà wá mọ́ tàbí fi ojú rí ilẹ̀ tí a ti bí i.
Yuda fi dunu! Hina bagade Yousaia ea hou dawa: beba: le mae dima! E bogobeba: le, mae da: i dioma! Be ea mano Youaha: se, amo dawa: beba: le, bagadewane didigia: ma. Bai ha lai dunu da e afugili oule ahoa. Amola ea soge amogawi e da lalelegei, amo e da bu hamedafa ba: mu.
11 Nítorí báyìí ni Olúwa wí, nípa Ṣallumu ọmọ Josiah ọba Juda tí ó jẹ ọba lẹ́yìn baba rẹ̀, ṣùgbọ́n tí ó jáde kúrò níhìn-ín: “Òun kì yóò padà wá mọ́.
Hina Gode da Yousaia ea mano Youaha: se (e da ea ada Yousaia, Yuda hina bagade amo ea sogebi lai) ea hou olelema: ne, amane sia: sa, “E da guiguda: yolesili, bu hamedafa buhagimusa: , asi dagoi.
12 Yóò kú ni ibi tí a mú u ní ìgbèkùn lọ, kì yóò sì rí ilẹ̀ yìí mọ́.”
Ea ha lai da e ga sogega afugili asi. E da amo sogega bogomu. Amola e da Yuda soge bu hamedafa ba: mu.”
13 “Ègbé ni fún ẹni tí a kọ́ ààfin rẹ̀ lọ́nà àìṣòdodo, àti àwọn yàrá òkè rẹ̀ lọ́nà àìtọ́ tí ó mú kí àwọn ará ìlú rẹ ṣiṣẹ́ lásán láìsan owó iṣẹ́ wọn fún wọn.
Nowa dunu da moloi hou hame hamoiba: le, liligi bagade lasea, e da wadela: lesi dagoi ba: mu. Nowa da ea fi dunuma hawa: hamomusa: sia: sea, be ilima bidi hame iaha, amo da wadela: lesi dagoi ba: mu.
14 Ó wí pé, ‘Èmi ó kọ́ ààfin ńlá fún ara mi àwọn yàrá òkè tí ó fẹ̀, ojú fèrèsé rẹ̀ yóò tóbi.’ A ó sì fi igi kedari bò ó, a ó fi ohun aláwọ̀ pupa ṣe é ní ọ̀ṣọ́.
Nowa dunu da amane sia: sa, “Na da diasu noga: iwane gagumu. Amo ganodini, fa: gu da: iya heda: le, gadodili sesei bagade na da gagumu.” Amasea, e da ea diasuga fo misa: ne agenesi hamosa amola dolo ifa amoga dobea fesa amola yoi ulasu amoga unasisa. Agoai dunu da wadela: lesi dagoi ba: mu.
15 “Ìwọ ó ha jẹ ọba kí ìwọ kí ó lè ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ igi kedari? Baba rẹ kò ha ní ohun jíjẹ àti mímu? Ó ṣe ohun tí ó tọ́ àti òdodo, nítorí náà ó dára fún un.
Di da diasu noga: idafa eno dunu ilia diasu baligisa amo dolo ifaga hamoiba: le, amo da dia hina bagade ouligisu hou baligili noga: iwane hahamoma: bela: ? Hame mabu! Dia ada da hahawane esalu. E da eso huluane moloidafa fawane hamosu. Amaiba: le, hou huluane e hamoi da hahawane heda: i.
16 Ó gbèjà òtòṣì àti aláìní, ohun gbogbo sì dára fún un. Bí a ti mọ̀ mí kọ́ ni èyí?” ni Olúwa wí.
E da hame gagui dunu ilima moloiwane fofada: i, amola hou huluane da hahawane ba: i. Agoaiwane hou hamobeba: le, amo dunu da Hina Gode dawa: , amo olelesa.
17 “Ṣùgbọ́n ojú rẹ àti ọkàn rẹ wà lára èrè àìṣòótọ́ láti ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ìnilára àti ìlọ́nilọ́wọ́gbà.”
Be di da disu liligi amola hou fawane dawa: sa. Amola di da wadela: i hame hamosu dunu medole legesa amola gasa fili, dia fi dunu banenesisa. Hina Gode da sia: i dagoi.
18 Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí, nípa Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda: “Wọn kì yóò ṣọ̀fọ̀ fún un: wí pé, ‘Ó ṣe, arákùnrin mi! Ó ṣe, arábìnrin mi!’ Wọn kì yóò ṣọ̀fọ̀ fún un: wí pé, ‘Ó ṣe, olúwa tàbí ó ṣe ọlọ́lá!’
Amaiba: le, Hina Gode da Yuda hina bagade Yihoiagimi (Yousaia egefe) amo ea hou olelema: ne amane sia: sa, ‘E da bogosea, dunu afae da da: i dione hame dimu. Ilia da ‘Sama! Amo da da: i dioi bagade liligi. Na hina! Na hina bagade!’ dinanawane amane hamedafa sia: mu.’
19 A ó sin òkú rẹ̀ bí i kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí a wọ́ sọnù láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu.”
Ilia da Yihoiagimi ea da: i hodo hame uli dogomu. Be ohe dougi bogoi amoma dawa: su defele, ilia da ea da: i hodo hiougili, Yelusaleme ea logo holeiga gadili, isu salasuga galagamu.”
20 “Gòkè lọ sí Lebanoni, kígbe síta, kí a sì gbọ́ ohùn rẹ ní Baṣani, kí o kígbe sókè láti Abarimu, nítorí a ti ṣẹ́ gbogbo olùfẹ́ rẹ túútúú.
Yelusaleme fi dunu! Dilia Lebanone sogega asili, wele sia: ma! Ba: isa: ne sogega asili, dima! Moua: be goumiga asili, wele sia: ma mabu! Bai dilia fidisu dunu huluane da hasali dagoi ba: sa.
21 Èmi ti kìlọ̀ fún ọ nígbà tí o rò pé kò séwu, ṣùgbọ́n o sọ pé, ‘Èmi kì yóò fetísílẹ̀!’ Èyí ni iṣẹ́ rẹ láti ìgbà èwe rẹ, ìwọ kò fìgbà kan gba ohùn mi gbọ́.
Dilia da hahawane bagade gaguiwane esaloba, Hina Gode da dilima sia: i dagoi. Be dilia da Ea sia: hame nabi. Dilia da eso huluane esaloba, agoaiwane hamosu. Dilia da Hina Gode Ea sia: nabimu hame dawa: i galu.
22 Ẹ̀fúùfù yóò lé gbogbo àwọn olùṣọ́-àgùntàn rẹ̀ lọ, gbogbo àwọn olùfẹ́ rẹ yóò lọ sí ìgbèkùn, nígbà náà ni a ó kẹ́gàn rẹ, ojú yóò tì ọ́ nítorí gbogbo ìwà búburú rẹ.
Dilia ouligisu dunu da foga gaguli asi dagoi ba: mu. Dilia ha lai dunu da dilimagale gegesu fidisu dunu amo udigili hawa: hamoma: ne, afugili oule masunu. Dilia wadela: le baligili hamoiba: le, dilia moilai bai bagade da gogosia: i dagoi ba: mu.
23 Ìwọ tí ń gbé ‘Lebanoni,’ tí ó tẹ́ ìtẹ́ sí orí igi kedari, ìwọ yóò ti kérora pẹ́ tó, nígbà tí ìrora bá dé bá ọ, ìrora bí i ti obìnrin tí ń rọbí!
Dilia da Lebanone sogega, dolo ifa bagohame lai, amola amoga gagui diasu ganodini dilia da waha olofoiwane esala. Be se nabasu da uda mano lalelegemu se nabasu defele, amo da dilima doaga: sea, dilia da da: i dione se nabawane ba: mu.
24 “Dájúdájú bí èmi ti wà láààyè,” ni Olúwa wí, “Bí Koniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda tilẹ̀ jẹ́ òrùka èdìdì lọ́wọ́ ọ̀tún mi, síbẹ̀ èmi ó fà ọ́ tu kúrò níbẹ̀.
Hina Gode da hina bagade Yehoiagini (Yuda hina bagade Yihoiagimi egefe) ema amane sia: i, “Na da Gode Esala. Na da Na lobodafa lobo sogo gasisalasu amoga asigi gala, amo defele dima asigi ganiaba, Na da di fadegale fasila: loba.
25 Èmi ó sì fà ọ́ lé ọwọ́ àwọn tí ó ń wá ẹ̀mí rẹ, àwọn tí ìwọ bẹ̀rù, àní lé ọwọ́ Nebukadnessari, ọba Babeli àti ọwọ́ àwọn ará Babeli.
Amola Na da di amo dunu fi (amo di da iliba: le beda: i - bai ilia di medole legemusa: dawa: lala) ilima ia: noba. Na da di Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese amola ea dadi gagui dunu ilima imunu.
26 Èmi ó fi ìwọ àti ìyá tí ó bí ọ sọ̀kò sí ilẹ̀ mìíràn, níbi tí a kò bí ẹnikẹ́ni nínú yín sí. Níbẹ̀ ni ẹ̀yin méjèèjì yóò kú sí.
Na da gasa fili, di amola dia ame mugululi masa: ne asunasimu. Alia da soge amoga alia hame lalelegei, amoga asili, bogomu.
27 Ẹ̀yin kì yóò padà sí ilẹ̀ tí ẹ̀yin fẹ́ mọ́ láéláé.”
Alia da Yuda soge bu ba: musa: bagade hanamu, be alia da amoga hamedafa buhagimu.”
28 Ǹjẹ́ Jehoiakini ẹni ẹ̀gàn yàtọ̀ sí ìkòkò òfìfo, ohun èlò tí ẹnìkan kò fẹ́? Èéṣe tí a fi òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ sókè sí ilẹ̀ tí wọn kò mọ̀.
Na (Yelemaia) da amane sia: i, “Hina bagade Yehoiagini da ganagu goudai amo dunu ilia da gagui dialumu higa: iba: le ha: digi dagoi, agoaiwane hamobela: ? E da agoane hamoiba: le, Di da e amola ea mano amo soge ilia hamedafa dawa: amoga asunasima: bela: ?”
29 Ìwọ ilẹ̀, ilẹ̀, ilẹ̀, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa!
Soge! Soge! Soge! Hina Gode Ea sia: i liligi huluane nabima!
30 Báyìí ni Olúwa wí: “Kọ àkọsílẹ̀ ọkùnrin yìí sínú ìwé gẹ́gẹ́ bí aláìlọ́mọ, ẹni tí kì yóò ṣe rere ní ọjọ́ ayé rẹ̀; nítorí ọ̀kan nínú irú-ọmọ rẹ̀ kì yóò ṣe rere, èyíkéyìí wọn kì yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi tàbí jẹ ọba ní Juda mọ́.”
“Na da amo dunuma fofada: i dagoiba: le, e da ea mano huluane fisimu. E da fa: no hahawane amola bagade gagui hou hame ba: mu amola didili hame hamomu. Egaga fi da Da: ibidi ea baligiga Yuda soge ouligisu hou hamedafa ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”