< Jeremiah 17 >

1 “Ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a fi kálámù irin kọ, èyí tí a fi ṣóńṣó òkúta adamante gbẹ́ ẹ, sórí wàláà oókan àyà wọn, àti sórí ìwo pẹpẹ yín.
Yehudaning gunahi almas uchluq tömür qelem bilen tashtaxtay kebi yüreklirige we qurban’gahliridiki münggüzlerge oyulghan;
2 Kódà àwọn ọmọ wọn rántí pẹpẹ àti ère Aṣerah lẹ́bàá igi tí ó tẹ́ rẹrẹ àti àwọn òkè gíga.
balilirimu yéshil derexler boyida tiklen’gen, égiz döngler üstide yasighan [butlirining] qurban’gahlirini we «Asherah»lirini herdaim séghinidu.
3 Àwọn òkè nínú ilẹ̀ àti àwọn ọrọ̀ rẹ̀ àti ọlá rẹ̀ ni èmi yóò fi sílẹ̀ bí ìjẹ pẹ̀lú àwọn ibi gíga, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó pọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè yín.
Men taghliringlarda we étizliringlarda, hem bayliqliringni hem xeziniliringni, — séning «yuqiri jaylar»ingmu buning sirtida emes — bu chétingdin u chétinggiche bolghan gunahing tüpeylidin olja bolushqa tapshurimen;
4 Láti ipasẹ̀ àìṣedéédéé yín ni ẹ̀yin yóò ti sọ ogún tí mo fún un yín nù. Èmi yóò fi yín fún ọ̀tá yín bí ẹrú ní ilẹ̀ tí ẹ̀yin kò mọ̀, nítorí ẹ̀yin ti mú inú bí mi, èyí tí yóò sì wà títí ayé.”
Özüngning shori, Men sanga teqdim qilghan mirasing qolungdin kétidu; Men sen tonumaydighan bir zéminda séni düshmenliringning qulluqigha tapshurimen; chünki siler ghezipimge ot yéqip uni qozghighansiler; u menggüge köyidu.
5 Báyìí ni Olúwa wí: “Ègbé ni fún àwọn tí ó fi ìgbẹ́kẹ̀lé wọn sínú ènìyàn, tí ó fi agbára rẹ̀ sínú ẹran-ara, àti tí ọkàn rẹ̀ kò sí lọ́dọ̀ Olúwa.
Perwerdigar mundaq deydu: — — Ademge tayan’ghan, ademning et-küchini tayanchi qilghan, qelbi Perwerdigardin chetnigen ademning haligha lenet bolsun!
6 Yóò dàbí igbó tí ó wà ní ilẹ̀ aláìlọ́ràá, kò ní rí ìre, nígbà tí ó bá dé, yóò máa gbé ní ibi ìyàngbẹ ilẹ̀ aginjù, ní ilẹ̀ iyọ̀ tí ẹnikẹ́ni kò gbé.
U chöl-bayawanda ösken qara archa chatqilidek bolidu; bext-yaxshiliq kelsimu u buni körmeydu; u belki chöldiki qaghjiraq yerlerde, ademzatsiz shorluq bir zéminda turidu.
7 “Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, tí ó sì fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ̀.
Perwerdigargha tayan’ghan, Perwerdigarni tayanch qilghan adem bext-beriketlik bolidu!
8 Yóò dàbí igi tí a gbìn sí ipadò tí ó ta gbòǹgbò rẹ̀ ká etí odò kò sí ìbẹ̀rù fún un nígbà ooru, gbogbo ìgbà ni èwe rẹ̀ máa ń tutù kò sí ìjayà fún un ní ọdún ọ̀dá bẹ́ẹ̀ ni kò ní dẹ́kun láti máa so èso.”
U sular boyida tiklen’gen, ériq boyida keng yiltiz tartqan derexdek; pizhghirim issiqtin u qorqmaydu; uning yopurmaqliri hemishe yéshildur; qurghaqchiliq yili u solashmaydu we méwe bérishtin qalmaydu.
9 Ọkàn ènìyàn kún fún ẹ̀tàn ju ohun gbogbo lọ, ó kọjá ohun tí a lè wòsàn. Ta ni èyí lè yé?
Qelb hemmidin aldamchi, uning dawasi yoqtur. Kimmu uni chüshinelisun?
10 “Èmi Olúwa ń wo ọkàn àti èrò inú ọmọ ènìyàn, láti san èrè iṣẹ́ rẹ̀ fún un gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.”
Menki Perwerdigar insan qelbini közitip tekshürimen; herbirsige öz yolliri boyiche, qilghan emellirining méwisi boyiche teqsim qilish üchün, insan wijdanini sinaymen.
11 Bí àparò tó pa ẹyin tí kò yé ni ọmọ ènìyàn tí ó kó ọrọ̀ jọ ni ọ̀nà àìṣòdodo. Yóò di ẹni ìkọ̀sílẹ̀ ní agbede-méjì ayé rẹ̀, àti ní òpin rẹ̀ yóò wá di aṣiwèrè.
Xuddi özi tughmighan tuxumlarni bésiwalghan kekliktek, haramdin bayliqlargha érishken kishimu shundaq bolidu; künlirining yérimi ötmeyla érishkinidin ayrilidu, u axirida exmeq bolup chiqidu.
12 Ìtẹ́ ògo; ibi gíga láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ní ibi ilé mímọ́ wa.
Shan-shereplik bir text, ezeldin yuqirigha tiklen’gen, del bizning bashpanahimiz bolghan jaydur;
13 Olúwa ìwọ ni ìrètí Israẹli; gbogbo àwọn tí ó kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ni ojú ó tì. Àwọn tí ó padà sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ ni a ó kọ orúkọ wọn sínú ekuru, nítorí wọ́n ti kọ Olúwa, orísun omi ìyè sílẹ̀.
i Perwerdigar, Sen Israilning ümidisen! Sendin waz kechken hemmeylen yerge qarap qalidu; Sendin yiraqlashqanlar tupraqta yatqanlar arisida tizimlinidu; chünki ular hayatliq sulirining menbesi bolghan Perwerdigardin waz kechken.
14 Wò mí sàn Olúwa, èmi yóò di ẹni ìwòsàn, gbà mí là, èmi yóò di ẹni ìgbàlà, nítorí ìwọ ni ìyìn mi.
Méni saqaytqin, i Perwerdigar, men shuning bilen jezmen saqaytilimen! Méni qutquzghin, shuning bilen jezmen qutquzulimen! — Chünki Özüng méning medhiyemdursen!
15 Wọ́n sọ fún mi wí pé: “Níbo ni ọ̀rọ̀ Olúwa wà? Jẹ́ kí ó di ìmúṣẹ báyìí.” Ni Olúwa wí.
Mana, ular manga: — Perwerdigarning söz-béshariti qéni?! Qéni, u emelge ashurulsun!» — deydu.
16 Èmi kò sá kúrò láti máa jẹ́ olùṣọ àgùntàn rẹ, ìwọ mọ̀ wí pé èmi kò kẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ ìpọ́njú. Ohun tí ó jáde ní ètè mi jẹ́ èyí tí ó hàn sí ọ.
Lékin men bolsam, Sanga egeshkinimde «pada baqquchi» bolushtin héch qachqan emesmen, we ejel künini héch arzu qilmighanmen, — Sen bilisen! Aghzimdin barliq chiqqanlar Séning yüz aldingda bolghan.
17 Má ṣe di ìbẹ̀rù fún mi, ìwọ ni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú.
Manga wehime bolmighaysen; külpetlik künide Sen méning bashpanahimdursen.
18 Jẹ́ kí ojú ti àwọn ẹni tí ń lépa mi, ṣùgbọ́n pa mí mọ́ kúrò nínú ìtìjú, jẹ́ kí wọn kí ó dààmú. Mú ọjọ́ ibi wá sórí wọn, fi ìparun ìlọ́po méjì pa wọ́n run.
Manga ziyankeshlik qilghuchilar yerge qarap qalsun, lékin méni yerge qaratmighaysen! Ular dekke-dükkige chüshsun, lékin méni dekke-dükkige chüshürmigeysen; ularning béshigha külpet künini chüshürgeysen; ularni ikki hessilik halaket bilen üzül-késil pachaqlap tashlighaysen!
19 Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún mi: “Lọ dúró ní ẹnu-ọ̀nà àwọn ènìyàn níbi tí àwọn ọba Juda ń gbà wọlé tí wọ́n ń gbà jáde àti ní gbogbo ẹnu-bodè Jerusalẹmu.
Perwerdigar manga mundaq dégen: — Barghin, Yehuda padishahliri sheherge kiridighan we chiqidighan «Xelqning baliliri» dégen derwazida, hemde Yérusalémning barliq derwazilirida turghin, ulargha mundaq dégin: —
20 Sọ fún wọ́n pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọba Juda àti gbogbo ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ẹ̀yin tí ń gbé ní Jerusalẹmu tí ń wọlé láti ẹnu ibodè yìí.
Perwerdigarning sözini anglanglar, i mushu derwazilardin kiridighan Yehudaning padishahliri, barliq Yehuda we Yérusalémda turuwatqan xalayiq!
21 Báyìí ni Olúwa wí, “Ẹ kíyèsi láti máa ru ẹrù lọ́jọ́ ìsinmi tàbí kí ẹ gbé wọlé láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu.
Perwerdigar mundaq deydu: — Öz jéninglargha hézi bolunglar! «shabat» künide héchqandaq yükni kötürmenglar, Yérusalémning derwaziliridin héchnersini épkirmenglar;
22 Má ṣe gbé ẹrù jáde kúrò nínú ilé yín, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi ṣùgbọ́n kí ẹ pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ fún àwọn baba ńlá yín.”
shabat künliride öyliringlardin héch yükni kötürüp élip chiqmanglar, we héchqandaq emgek qilmanglar; belki Men ata-bowiliringlargha buyrughinimdek, shabat künini Özümge atalghan muqeddes bir kün dep qaranglar.
23 Síbẹ̀ wọn kò gbọ́ tàbí tẹ́tí sílẹ̀, wọ́n jẹ́ ọlọ́rùn líle; wọn kì í fẹ́ gbọ́ tàbí gba ìbáwí.
Lékin ular héch anglimighan yaki qulaq salmighan, belki anglimasliqqa hem terbiyini qobul qilmasliqqa boynini qattiq qilghan.
24 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kíyèsi láti gbọ́ tèmi ní Olúwa wí, tí ẹ kò sì gbe ẹrù gba ẹnu-bodè ìlú ní ọjọ́ ìsinmi, ṣùgbọ́n tí ẹ ya ọjọ́ ìsinmi, sí mímọ́, nípa pé ẹ kò ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ náà.
Shundaq boliduki, siler awazimni köngül qoyup anglisanglar, — deydu Perwerdigar, — yeni shabat künide sheher derwaziliridin héch yükni élip kirmisenglar we héch emgek qilmasliq arqiliq shabat künini Manga pak-muqeddes bir kün hésablisanglar,
25 Nígbà náà ni ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba ẹnu ibodè wọlé pẹ̀lú àwọn ìjòyè rẹ̀. Àwọn àti ìjòyè wọn yóò gun ẹṣin àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wá, àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu yóò tẹ̀lé wọn; ìlú yìí yóò sì di ibi gbígbé títí láéláé.
bu sheher derwaziliridin Dawutning textige olturidighan padishahliri we emirliri jeng harwilirigha olturup we atlargha minip kiridu; ular, ularning emirliri, Yehudadikiler we Yérusalémda turuwatqanlarmu kirip-chiqishidu; bu sheher menggü awat bolidu.
26 Àwọn ènìyàn yóò wá láti ìlú Juda àti ní agbègbè Jerusalẹmu, láti ilẹ̀ Benjamini, láti pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti láti òkè, àti láti gúúsù wá, wọn yóò wá pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun, àti ọrẹ ẹran, àti tùràrí, àti àwọn tó mú ìyìn wá sí ilé Olúwa.
Shundaq qilsanglar, xelqler Yehuda sheherliridin, Yérusalém etrapidiki yézilardin, Binyaminning zéminidin, [gherbtiki] «Shefelah» égizlikidin, jenubtiki [taghliqtin], Yehudadiki jenubiy bayawanlardin Perwerdigarning öyige «köydürme qurbanliq»lar, «inaqliq qurbanliqliri», «ashliq hediye»ler we xushbuylarni tutup, [Perwerdigargha bolghan] rehmetlirini éytishqa kiridighan bolidu.
27 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá pa òfin mi mọ́ láti ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́, kí ẹ má sì ṣe ru ẹrùkẹ́rù bí ẹ̀yin yóò ṣe máa gba ẹnu ibodè Jerusalẹmu wọlé ní ọjọ́ ìsinmi, nígbà náà ni èmi yóò da iná tí kò ní ṣe é parun ní ẹnu-bodè Jerusalẹmu tí yóò sì jó odi agbára rẹ̀.’”
Lékin siler Manga qulaq salmisanglar, yeni shabat künini Özümge pak-muqeddes hésablimay, shabat künide Yérusalémning derwaziliridin yük kötürüp kirsenglar, emdi Men derwazilargha bir ot yaqimen, u Yérusalémdiki ordilarni yewétidu, uni héch öchürelmeydu.

< Jeremiah 17 >