< Jeremiah 17 >

1 “Ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a fi kálámù irin kọ, èyí tí a fi ṣóńṣó òkúta adamante gbẹ́ ẹ, sórí wàláà oókan àyà wọn, àti sórí ìwo pẹpẹ yín.
Judah zaehaih loe sum cacung, diamond thlung kamsum hoiah tarik pae boeh, na hmaicam takiinawk nuiah tarik ih baktiah nihcae palung thungah tarik pae boeh;
2 Kódà àwọn ọmọ wọn rántí pẹpẹ àti ère Aṣerah lẹ́bàá igi tí ó tẹ́ rẹrẹ àti àwọn òkè gíga.
a caanawk mah doeh maesom nui ih kahing thingnawk taengah, angmacae ih hmaicamnawk to suek o moe, thing hoi sak o cop ih krangnawk to bok o.
3 Àwọn òkè nínú ilẹ̀ àti àwọn ọrọ̀ rẹ̀ àti ọlá rẹ̀ ni èmi yóò fi sílẹ̀ bí ìjẹ pẹ̀lú àwọn ibi gíga, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó pọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè yín.
Aw kai ih mae, azawn ih hmuenmaenawk, na tawnh ih tacongnawk hoi na prae thungah zae sak haih hmuensangnawk boih to na misanawk ban ah ka paek han boeh.
4 Láti ipasẹ̀ àìṣedéédéé yín ni ẹ̀yin yóò ti sọ ogún tí mo fún un yín nù. Èmi yóò fi yín fún ọ̀tá yín bí ẹrú ní ilẹ̀ tí ẹ̀yin kò mọ̀, nítorí ẹ̀yin ti mú inú bí mi, èyí tí yóò sì wà títí ayé.”
Kang paek ih qawk to na pathlong ving tih boeh; kadueh thai ai palung ka phuihaih hmai baktiah angqong hanah na sak pongah, na panoek ai ih prae ah na misanawk ih misong ah kang suek han.
5 Báyìí ni Olúwa wí: “Ègbé ni fún àwọn tí ó fi ìgbẹ́kẹ̀lé wọn sínú ènìyàn, tí ó fi agbára rẹ̀ sínú ẹran-ara, àti tí ọkàn rẹ̀ kò sí lọ́dọ̀ Olúwa.
Angraeng mah hae tiah thuih; Angraeng khae hoi poek amkhraeng ving moe, minawk oep lat kami, taksa thacakhaih oep kami loe kasae tongh kami ah oh.
6 Yóò dàbí igbó tí ó wà ní ilẹ̀ aláìlọ́ràá, kò ní rí ìre, nígbà tí ó bá dé, yóò máa gbé ní ibi ìyàngbẹ ilẹ̀ aginjù, ní ilẹ̀ iyọ̀ tí ẹnikẹ́ni kò gbé.
Anih loe long karoem ahmuen ih thing kazaek baktiah oh, khosak hoihaih hnu mak ai; anih loe kami om ai paloi long hoi praezaek ahmuen ah khosah tih.
7 “Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, tí ó sì fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ̀.
Toe Angraeng khaeah amha moe, anih oephaih tawn kami loe tahamhoih.
8 Yóò dàbí igi tí a gbìn sí ipadò tí ó ta gbòǹgbò rẹ̀ ká etí odò kò sí ìbẹ̀rù fún un nígbà ooru, gbogbo ìgbà ni èwe rẹ̀ máa ń tutù kò sí ìjayà fún un ní ọdún ọ̀dá bẹ́ẹ̀ ni kò ní dẹ́kun láti máa so èso.”
Anih loe tui taengah thling moe, tuipui ah tangzun pakhrah, ni kana panoek ai, aqam kahing poe, khokha naah mawnhaih tawn ai, boeng ai ah kathai, thing baktiah om tih.
9 Ọkàn ènìyàn kún fún ẹ̀tàn ju ohun gbogbo lọ, ó kọjá ohun tí a lè wòsàn. Ta ni èyí lè yé?
Palung loe hmuennawk boih thungah aling thaih koek ah oh; poekhaih doeh set parai, mi mah maw anih to panoek thai tih?
10 “Èmi Olúwa ń wo ọkàn àti èrò inú ọmọ ènìyàn, láti san èrè iṣẹ́ rẹ̀ fún un gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.”
Kai, Angraeng loe kami boih a caeh o haih loklam baktih, a sak o ih hmuen baktih toengah paek hanah, poekhaih to ka khet moe, palungthin to ni ka caek.
11 Bí àparò tó pa ẹyin tí kò yé ni ọmọ ènìyàn tí ó kó ọrọ̀ jọ ni ọ̀nà àìṣòdodo. Yóò di ẹni ìkọ̀sílẹ̀ ní agbede-méjì ayé rẹ̀, àti ní òpin rẹ̀ yóò wá di aṣiwèrè.
Toenghaih loklam hoi na ai ah hmuenmae pakrong pongah, angraeng kami loe acaa khaek thai mak ai, angmah ih tadui awh ai tavaa baktiah ni oh; a hinghaih saning ahap phak naah, minawk mah caeh o taak tih, anih amthuhaih loe hnukkhuem ah amtueng tih.
12 Ìtẹ́ ògo; ibi gíga láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ní ibi ilé mímọ́ wa.
Tangsuek hoi kaom lensawk kasang angraeng tangkhang loe, kaicae ih hmuenciim ah oh.
13 Olúwa ìwọ ni ìrètí Israẹli; gbogbo àwọn tí ó kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ni ojú ó tì. Àwọn tí ó padà sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ ni a ó kọ orúkọ wọn sínú ekuru, nítorí wọ́n ti kọ Olúwa, orísun omi ìyè sílẹ̀.
Aw Angraeng, Israel caanawk oephaih, Nang pahnawt kaminawk boih loe azathaih tong o tih; ka thuih ih lok angqoi taak kaminawk loe hinghaih tuibap ah kaom, Angraeng to pahnawt o ving pongah, long ah ahmin tarik o tih.
14 Wò mí sàn Olúwa, èmi yóò di ẹni ìwòsàn, gbà mí là, èmi yóò di ẹni ìgbàlà, nítorí ìwọ ni ìyìn mi.
Aw Angraeng, ka nathaih hae hoisak ah; to tih nahaeloe ngan ka tui tih boeh; na pahlong ah, to tih nahaeloe pahlong ah ka om tih, nang loe ka pakoehhaih ah na oh.
15 Wọ́n sọ fún mi wí pé: “Níbo ni ọ̀rọ̀ Olúwa wà? Jẹ́ kí ó di ìmúṣẹ báyìí.” Ni Olúwa wí.
Khenah, nihcae mah kai khaeah, Angraeng ih lok loe naa ah maw oh? Vaihi akoep lai nasoe, tiah ang naa o.
16 Èmi kò sá kúrò láti máa jẹ́ olùṣọ àgùntàn rẹ, ìwọ mọ̀ wí pé èmi kò kẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ ìpọ́njú. Ohun tí ó jáde ní ètè mi jẹ́ èyí tí ó hàn sí ọ.
Kai loe nang hnuk ah kabang zaehoikung ah oh hanah kang aek ai; kai loe tahamsethaih ani koeh ai kami ah ka oh, tiah na panoek; ka pakha hoi tacawt lok loe na hmaa ah oh.
17 Má ṣe di ìbẹ̀rù fún mi, ìwọ ni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú.
Kai han zit koi hmuen ah om hmah; kam rohaih niah nang loe ka buephaih ah na oh.
18 Jẹ́ kí ojú ti àwọn ẹni tí ń lépa mi, ṣùgbọ́n pa mí mọ́ kúrò nínú ìtìjú, jẹ́ kí wọn kí ó dààmú. Mú ọjọ́ ibi wá sórí wọn, fi ìparun ìlọ́po méjì pa wọ́n run.
Kai pacaekthlaek kaminawk loe azathaih tong o nasoe, toe kai loe azathaih na tongsak hmah; nihcae to zithaih hoiah koisak ah, toe kai loe ziisak hmah; nihcae nuiah amrohaih ani to phasak ah loe, nihcae to alet hnetto amrohaih phasak ah.
19 Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún mi: “Lọ dúró ní ẹnu-ọ̀nà àwọn ènìyàn níbi tí àwọn ọba Juda ń gbà wọlé tí wọ́n ń gbà jáde àti ní gbogbo ẹnu-bodè Jerusalẹmu.
Angraeng mah kai khaeah hae tiah thuih; Caeh ah loe, Judah siangpahrangnawk akunhaih hoi tacawthaih khongkha, nawktanawk ih khongkha hoi Jerusalem ih khongkhanawk boih ah angdoe ah,
20 Sọ fún wọ́n pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọba Juda àti gbogbo ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ẹ̀yin tí ń gbé ní Jerusalẹmu tí ń wọlé láti ẹnu ibodè yìí.
nihcae khaeah, Hae khongkha hoiah akun, Judah siangpahrangnawk, Judah kaminawk boih, Jerusalem ah kaom kaminawk boih, Angraeng ih lok hae tahngai oh;
21 Báyìí ni Olúwa wí, “Ẹ kíyèsi láti máa ru ẹrù lọ́jọ́ ìsinmi tàbí kí ẹ gbé wọlé láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu.
Angraeng mah hae tiah thuih; Sabbath niah kazit hmuen to phaw o hmah, Jerusalem khongkha thung hoiah kawbaktih hmuen doeh sin han ai ah, acoe oh:
22 Má ṣe gbé ẹrù jáde kúrò nínú ilé yín, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi ṣùgbọ́n kí ẹ pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ fún àwọn baba ńlá yín.”
Sabbath niah imthung hoi kazit hmuen to phaw o hmah, tok doeh sah o hmah, nam panawk khaeah ka thuih pae ih lok baktih toengah, Sabbath ni to kaciim ah zaa oh.
23 Síbẹ̀ wọn kò gbọ́ tàbí tẹ́tí sílẹ̀, wọ́n jẹ́ ọlọ́rùn líle; wọn kì í fẹ́ gbọ́ tàbí gba ìbáwí.
Toe nihcae mah tahngai o ai, naa doeh patueng o ai; a thaih o han ai, thuitaekhaih lok talawk o han ai ah, tahnong to amtaak o sak.
24 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kíyèsi láti gbọ́ tèmi ní Olúwa wí, tí ẹ kò sì gbe ẹrù gba ẹnu-bodè ìlú ní ọjọ́ ìsinmi, ṣùgbọ́n tí ẹ ya ọjọ́ ìsinmi, sí mímọ́, nípa pé ẹ kò ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ náà.
Toe Angraeng mah hae tiah thuih; ka lok hae na tahngaih o moe, Sabbath niah hae khongkhanawk hoiah kazit hmuen na sin o ai, toksah ai ah Sabbath ni to kaciim ah na zah o nahaeloe,
25 Nígbà náà ni ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba ẹnu ibodè wọlé pẹ̀lú àwọn ìjòyè rẹ̀. Àwọn àti ìjòyè wọn yóò gun ẹṣin àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wá, àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu yóò tẹ̀lé wọn; ìlú yìí yóò sì di ibi gbígbé títí láéláé.
David ih angraeng tangkhang pongah anghnu, siangpahrang hoi siangpahrang capanawk, hrang lakok hoi hrang angthueng kaminawk, angmacae hoi angmacae ukkung angraengnawk, Judah kaminawk hoi Jerusalem ah kaom kaminawk loe, hae khongkhanawk hoiah akun o tih, hae vangpui doeh dungzan khoek to cak poe tih.
26 Àwọn ènìyàn yóò wá láti ìlú Juda àti ní agbègbè Jerusalẹmu, láti ilẹ̀ Benjamini, láti pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti láti òkè, àti láti gúúsù wá, wọn yóò wá pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun, àti ọrẹ ẹran, àti tùràrí, àti àwọn tó mú ìyìn wá sí ilé Olúwa.
Judah avang, Jerusalem taeng ih avang, Benjamin prae ih avang, tangtling ah kaom avang, mae nui hoi aloih bang prae ah kaom kaminawk loe Angraeng ih im ah angzo o tih. Nihcae loe angbawnhaih congca, hmai angbawnhaih, moi angbawnhaih, hmuihoih angbawnhaih, pakoeh angbawnhaih to sin o tih.
27 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá pa òfin mi mọ́ láti ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́, kí ẹ má sì ṣe ru ẹrùkẹ́rù bí ẹ̀yin yóò ṣe máa gba ẹnu ibodè Jerusalẹmu wọlé ní ọjọ́ ìsinmi, nígbà náà ni èmi yóò da iná tí kò ní ṣe é parun ní ẹnu-bodè Jerusalẹmu tí yóò sì jó odi agbára rẹ̀.’”
Toe Sabbath niah hmuen phawh moe, Jerusalem khongkha ah akun pacoengah, Sabbath ni to kaciim ah zah han oh; ka paek ih lok to tahngai ai nahaeloe, to ih khongkhanawk to hmai hoiah ka thlaek han, kadueh thai ai hmai mah Jerusalem angraeng ohhaih ahmuennawk to kang boih tih, tiah Angraeng mah thuih.

< Jeremiah 17 >