< Jeremiah 16 >

1 Bákan náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Ang pulong ni Jehova midangat usab kanako, nga nagaingon:
2 “Ìwọ kò gbọdọ̀ ní ìyàwó, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ní ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin níbí yìí.”
Dili ka mangasawa, ni magbaton ka ug mga anak nga lalake kun mga anak nga babaye, niining dapita.
3 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí nípa ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin tí wọ́n bá bí nílẹ̀ yìí, àti ìyá tí ó bí wọn àti baba wọn.
Kay mao kini ang giingon ni Jehova mahitungod sa mga anak nga lalake ug sa mga anak nga babaye nga mangatawo niining dapita, ug mahitungod sa ilang mga inahan nga manganak kanila, ug mahitungod sa ilang mga amahan nga nagpakatawo kanila dinhi niining yutaa:
4 “Wọn yóò kú ikú ààrùn, wọn kò ní sin wọ́n tàbí ṣọ̀fọ̀ fún wọn. Wọn ó dàbí ìdọ̀tí lórí ilẹ̀; wọn ó ṣègbé pẹ̀lú idà àti ìyàn. Òkú wọn yóò sì di oúnjẹ fún ẹyẹ ojú ọ̀run àti ẹranko ilẹ̀.”
Sila mangamatay sa kamatayon nga makalilisang uyamut; sila dili pagahilakan; ni igalubong sila; sila mahimong sama sa kinalibang sa ibabaw sa nawong sa yuta; ug pagalamyon sila sa espada, ug sa gutom; ug ang ilang mga minatay mahimong kalan-on sa mga langgam sa kalangitan, ug alang sa mga mananap sa yuta.
5 Nítorí báyìí ni Olúwa wí: “Má ṣe wọ ilé tí oúnjẹ ìsìnkú wà, má ṣe lọ síbẹ̀ láti káàánú tàbí ṣọ̀fọ̀, nítorí mo ti mú àlàáfíà, ìfẹ́ àti àánú mi kúrò lórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí,” ni Olúwa wí.
Kay mao kini ang giingon ni Jehova: Ayaw pagsulod sa balay nga pagabalataan, ni moadto ka sa pagbakho, ni sa pagminatay kanila; kay ginakuha ko na ang akong pakigdait gikan niini nga katawohan, nagaingon si Jehova, bisan ngani ang mahigugmaong-kalolot ug ang malomong mga kalooy.
6 “Àti ẹni ńlá àti kékeré ni yóò ṣègbé ní ilẹ̀ yìí, wọn kò ní sin wọ́n tàbí ṣọ̀fọ̀ wọn, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí yóò fá irun orí wọn nítorí wọn.
Ang mga dagku ug ang mga gagmay mangamatay dinhi niining yutaa: sila dili igalubong, ni ang mga tawo managbakho alang kanila, ni managsamad sa ilang kaugalingon; ni managpaupaw sa ilang kaugalingon alang kanila;
7 Kò sí ẹni tí yóò fi oúnjẹ tu àwọn tí í ṣọ̀fọ̀ nínú, kódà kì í ṣe fún baba tàbí fún ìyá, kì yóò sí ẹni tí yóò fi ohun mímu tù wọ́n nínú.
Ni managtipak ug tinapay ang mga tawo alang kanila sa pagbalata, sa paglipay kanila tungod sa mga minatay; ni ang mga tawo managhatag kanila ug copa sa paglipay aron pagaimnom alang sa ilang amahan kun sa ilang inahan.
8 “Ìwọ kò gbọdọ̀ lọ sí ilé tí àjọyọ̀ wà, má ṣe jókòó jẹun tàbí mu ohun mímu.
Ug ayaw pag-adto sa balay nga kombirahan aron sa paglingkod uban kanila, sa pagkaon ug sa pag-inum.
9 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli wí, Ní ojú yín ní ọjọ́ yín ni òpin yóò dé bá ìró ayọ̀ àti ìdùnnú, àti sí ohùn ìyàwó àti ọkọ ìyàwó ní ibí yìí.
Kay mao kini ang giingon ni Jehova sa mga panon, ang Dios sa Israel: Ania karon, pahunongon ko niining dapita sa atubangan sa inyong mga mata ug sa inyong mga adlaw ang tingog sa kasadya, ug ang tingog sa kalipay, ang tingog sa kaslonon nga lalake ug ang tingog sa kaslonon nga babaye.
10 “Nígbà tí o bá sọ nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn yìí, tí wọ́n bá sì bi ọ́ wí pé, ‘Èéṣe tí Olúwa ṣe mú búburú yìí bá wa? Kí ni àṣìṣe tí àwa ṣe? Kín ni ẹ̀ṣẹ̀ tí àwa ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa?’
Ug mahatabo nga sa diha nga imantala mo niini nga katawohan kining tanan nga mga pulong, ug sila moingon kanimo: Ngano man nga nagsulti si Jehova niining tanan nga dagkung kadaut batok kanamo? kun unsay among kadautan? kun unsay among sala nga nahimo batok kang Jehova nga among Dios?
11 Nígbà náà ni ìwọ yóò sọ fún wọn wí pé, ‘Nítorí tí àwọn baba yín ti kọ̀ mí sílẹ̀,’ ni Olúwa wí, ‘tí wọ́n sì tẹ̀lé àwọn òrìṣà mìíràn tí wọ́n ń bọ, tí wọ́n ń sìn, wọ́n kọ̀ mí sílẹ̀ wọn kò sì tẹ̀lé òfin mi mọ́.
Unya ingnon mo sila: Tungod kay ang inyong mga amahan mingbiya kanako, nagaingon si Jehova, ug mingsunod sa laing mga dios, ug nanag-alagad kanila, ug nanagsimba kanila, ug mingbiya kanako, ug wala managbantay sa akong Kasugoan;
12 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti ṣe búburú ju ti àwọn baba yín lọ. Wò ó bí gbogbo yín ṣe ń rìn, olúkúlùkù yín nínú agídí ọkàn búburú rẹ̀, dípò kí ẹ fi gbọ́ tèmi.
Ug labaw ang kangil-ad nga inyong nahimo kay sa nahimo sa inyong mga amahan; kay, ania karon, kamong tagsatagsa nagasunod sa katig-a sa inyong dautan nga kasingkasing, mao nga kamo wala managpatalinghug kanako.
13 Èmi yóò gbé yin kúrò ní ilẹ̀ yìí lọ sí ilẹ̀ tí baba yín tàbí ẹ̀yin kò mọ̀ rí, níbẹ̀ ni ẹ̀yin yóò ti máa sìn ọlọ́run kéékèèké ní ọ̀sán àti òru nítorí èmi kì yóò fi ojúrere wò yín.’
Busa hinginlan ko kamo niining yutaa ngadto sa yuta nga wala ninyo hingbaloi, ni kamo, ni ang inyong mga amahan; ug didto manag-alagad kamo sa laing mga dios sa adlaw ug sa gabii; kay ako dili magapakita kaninyo ug kalooy.
14 “Nítorí náà, ọjọ́ náà ń bọ̀ wá,” ni Olúwa wí, “tí àwọn ènìyàn kò ní sọ pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè Olúwa ń bẹ, Ẹni tí ó mú Israẹli jáde kúrò ní Ejibiti.’
Busa, ania karon, ang mga adlaw ania na, nagaingon si Jehova, nga dili na pagaingnon: Ingon nga ang dios buhi, nga nagdala sa mga anak sa Israel gawas sa yuta sa Egipto;
15 Ṣùgbọ́n wọn yóò sọ wí pé, ‘Bí Olúwa ṣe wà nítòótọ́ tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ àríwá àti ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó ti lé wọn.’ Bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò dá wọn padà sí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá wọn.
Kondili, mao kini: Ingon nga si Jehova buhi, nga nagdala sa mga anak sa Israel gikan sa yuta sa amihanan, ug gikan sa tanang mga yuta diin sila giabog niya. Ug akong dad-on sila pag-usab ngadto sa ilang yuta nga gihatag ko sa ilang mga amahan.
16 “Ṣùgbọ́n báyìí, Èmi yóò ránṣẹ́ sí àwọn apẹja púpọ̀,” ni Olúwa wí. “Wọn ó sì dẹ wọ́n lẹ́yìn èyí yìí èmi yóò ránṣẹ́ sí àwọn ọdẹ púpọ̀, wọn yóò dẹ wọ́n lórí gbogbo òkè ńlá àti òkè gíga, àti ní gbogbo pálapàla àpáta.
Ania karon, ako magpakuha ug daghang mangingisda, nagaingon si Jehova, ug sila mangisda kanila; ug sa human niini magapadala ako ug daghang mga mangangayam, ug sila mangayam kanila gikan sa tagsatagsa ka bukid, ug gikan sa tagsatagsa ka bungtod, ug gikan sa mga lungag sa mga pangpang.
17 Ojú mi wà ní gbogbo ọ̀nà wọn, wọn kò pamọ́ fún mi bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀ṣẹ̀ wọn kò fi ara sin lójú mi.
Kay ang akong mga mata anaa sa tanan nilang ginalaktan; sila dili magtago gikan sa akong nawong, ni matago sa akong mga mata ang ilang kasal-anan.
18 Èmi yóò san ẹ̀san ìwà búburú àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún wọn ní ìlọ́po méjì, nítorí wọ́n ti ba ilẹ̀ mi jẹ́ pẹ̀lú àwọn ère wọn aláìlẹ́mìí, wọ́n sì fi òkú àti ohun ẹ̀gbin àti ìríra wọn kún ilẹ̀ ìní mi.”
Ug baslan ko pag-una ang ilang kasal-anan, ug ang ilang sala nga pinilo; tungod kay ilang gihugawan ang akong yuta sa mga minatay sa ilang mga butang nga makaluod, ug ilang gipuno ang akong panulondon sa ilang mga dulumtanan.
19 Olúwa, alágbára àti okun mi, ẹni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú, àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá láti òpin ayé wí pé, “Àwọn baba ńlá wa kò ní ohun kan bí kò ṣe ẹ̀gbin òrìṣà, ìríra tí kò dára fún wọn nínú rẹ̀.
Oh Jehova, akong kalig-on, ug akong kuta, ug akong dalangpanan sa panahon sa akong kasakitan, ang mga nasud moanha kanimo gikan sa mga kinatumyan sa yuta, ug manag-ingon: Sa walay duhaduha lonlon kabakakan ang napanunod sa atong mga amahan, bisan ang mga kakawangan ug mga butang nga walay kapuslanan.
20 Ṣé àwọn ènìyàn lè dá Ọlọ́run fún ara wọn bí? Bẹ́ẹ̀ ni, ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí kì í ṣe Ọlọ́run.”
Ang tawo magabuhat ba ug mga dios alang sa iyang kaugalingon, nga bisan pa dili diay mga dios?
21 “Nítorí náà, Èmi yóò kọ́ wọn ní àkókò yìí, Èmi yóò kọ́ wọn pẹ̀lú agbára àti títóbi mi. Nígbà náà ni wọn ó mọ pé orúkọ mi ní Olúwa.
Busa, ania karon, sila pahibaloon ko, niining makasua pa sila pahibaloon ko sa akong kamot ug sa akong kusog; ug sila mahibalo nga ang akong ngalan mao si Jehova.

< Jeremiah 16 >