< Isaiah 1 >

1 Ìran sí Juda àti Jerusalẹmu èyí tí Isaiah ọmọ Amosi rí ní àsìkò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah àwọn ọba Juda.
Maya nĩmo maũndũ marĩa maaguũrĩirio Isaia mũrũ wa Amozu, makoniĩ Juda na Jerusalemu hĩndĩ ya wathani wa Uzia, na wa Jothamu, na wa Ahazu, na wa Hezekia, arĩa maarĩ athamaki a Juda.
2 Gbọ́ ẹ̀yin ọ̀run! Fi etí sílẹ̀, ìwọ ayé! Nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀: “Mo tọ́ àwọn ọmọ dàgbà, ṣùgbọ́n wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi.
Atĩrĩrĩ, wee igũrũ, ta thikĩrĩria! Nawe thĩ ta igua! Nĩgũkorwo Jehova nĩarĩtie akoiga atĩrĩ: “Niĩ heete ciana irio, ngacirera igakũra, no cio ikaanemera.
3 Màlúù mọ olówó rẹ̀, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sì mọ ibùjẹ olówó rẹ̀, ṣùgbọ́n Israẹli kò mọ̀, òye kò yé àwọn ènìyàn mi.”
Ndegwa nĩyũũĩ mwene yo, nayo ndigiri ĩkamenya mũharatĩ wa mwene yo, no Isiraeli ndarĩ ũndũ ooĩ, andũ akwa nĩmagĩte ũmenyo.”
4 Á à! Orílẹ̀-èdè ẹlẹ́ṣẹ̀, àwọn ènìyàn tí ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ń pa lẹ́rù, ìran àwọn aṣebi, àwọn ọmọ tó ti di aṣèbàjẹ́! Wọn ti kọ Olúwa sílẹ̀ wọn ti gan Ẹni Mímọ́ Israẹli, wọn sì ti kẹ̀yìn sí i.
Hĩ! Kaĩ mũrĩ rũrĩrĩ rwĩhagia-ĩ. Mũrĩ andũ matitikĩte mahĩtia, na rũruka rwa andũ mekaga ũũru, na ciana ciĩrutĩire gũthũkia maũndũ! Nĩmatiganĩirie Jehova; nĩmamenete Ũrĩa Mũtheru wa Isiraeli, makamũhutatĩra, magacooka na thuutha.
5 Èéṣe tí a ó fi tún lù yín mọ́? Èéṣe tí ẹ ò dẹ́kun ọ̀tẹ̀ ṣíṣe? Gbogbo orí yín jẹ́ kìkì ọgbẹ́, gbogbo ọkàn yín sì ti pòruurù.
Nĩ kĩĩ gĩgũtũma mwende gũikara mũkĩhũũragwo? Nĩ kĩĩ gĩgũtũma mũthiĩ o na mbere kũrema? Mũtwe wothe nĩmũtihangie, nayo ngoro yothe ĩkanyamarĩka.
6 Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín dé àtàrí yín kò sí àlàáfíà rárá, àyàfi ọgbẹ́ òun ìfarapa àti ojú egbò, tí a kò nù kúrò tàbí kí á dì tàbí kí a kùn ún ní òróró.
Kuuma ikinya rĩa kũgũrũ nginya mũtwe gũtirĩ handũ hagima: no nguraro theri, na mĩtũnda, na ironda cia ndĩĩra itarĩ thambie, kana ikoohwo, kana ikororoiyo na maguta.
7 Orílẹ̀-èdè yín dahoro, a dáná sun àwọn ìlú yín, oko yín ni àwọn àjèjì ti jẹ run lójú ara yín náà, ni gbogbo rẹ̀ ṣòfò bí èyí tí àwọn àjèjì borí rẹ̀.
Bũrũri wanyu ũkirĩte ihooru, matũũra manyu manene magacinwo na mwaki; mĩgũnda yanyu ĩramathwo ĩgatigwo ũtheri nĩ andũ a kũngĩ o mũkĩonaga, ĩkoonũhwo ta ĩngʼaũranĩtio nĩ ageni.
8 Ọmọbìnrin Sioni ni a fi sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àtíbàbà nínú ọgbà àjàrà, gẹ́gẹ́ bí abà nínú oko ẹ̀gúnsí, àti bí ìlú tí a dó tì.
Mwarĩ wa Zayuni atiganĩirio ta gĩthũnũ kĩrĩ mũgũnda wa mĩthabibũ, agatiganĩrio ta kanyũmba karĩ mũgũnda wa marenge, o na ta itũũra inene rĩthiũrũrũkĩirio nĩ thũ ikĩenda kũrĩtunyana.
9 Àyàfi bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun bá ṣẹ́ díẹ̀ kù fún wà, a ò bá ti rí bí Sodomu, a ò bá sì ti dàbí Gomorra.
Tiga Jehova Mwene-Hinya-Wothe aatũtigĩirie matigari manini ma andũ-rĩ, tũngĩtuĩkĩte ta Sodomu, na tũkahaana ta Gomora!
10 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin aláṣẹ Sodomu, tẹ́tí sí òfin Ọlọ́run wa, ẹ̀yin ènìyàn Gomorra!
Thikĩrĩriai kiugo kĩa Jehova, inyuĩ mwathanaga Sodomu; na mũigue watho wa Ngai witũ, inyuĩ andũ a Gomora!
11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín kín ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín jásí fún mi?” ni Olúwa wí. “Mo ti ní ànító àti àníṣẹ́kù ẹbọ sísun ti àgbò àti ọ̀rá ẹran àbọ́pa, Èmi kò ní inú dídùn nínú ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù, ti àgùntàn àti ti òbúkọ.
“Magongona macio manyu mũndutagĩra maingĩ-rĩ, nĩ ma kĩ kũrĩ niĩ?” Ũguo nĩguo Jehova ekũũria. “Nĩnjiganĩtwo nĩ magongona ma njino, na magongona ma ndũrũme, na maguta ma nyamũ noru; niĩ ndikenagĩra thakame ya ndegwa, na ya tũtũrũme, o na ya mbũri.
12 Nígbà tí ẹ wá farahàn níwájú mi, ta ni ó béèrè èyí lọ́wọ́ yín, gìrì gìrì ẹsẹ̀ nínú àgbàlá mi?
Nũũ ũkoragwo amwĩrĩte mũndutĩre magongona macio rĩrĩa mũgũũka mbere yakwa kũũhooya, mũkĩrangaga nja cia nyũmba yakwa?
13 Ẹ má mú ọrẹ asán wá mọ́! Ìríra ni tùràrí yín jásí fún mi, oṣù tuntun àti ọjọ́ ìsinmi àti àwọn àpéjọ, Èmi kò lè faradà á, ẹ̀ṣẹ̀ ni àpéjọ yín wọ̀nyí.
Tigai gũcooka kũrehe maruta ma tũhũ! Ũbumba wanyu nĩ kĩndũ kĩa magigi harĩ niĩ. Ndingĩhota gũkirĩrĩria ciũngano cianyu cia waganu: mĩcemanio yanyu ya Karũgamo ka Mweri, na Thabatũ, o na ciathĩ iria njathane.
14 Ayẹyẹ oṣù tuntun yín àti àjọ̀dún tí a yàn, ni ọkàn mi kórìíra. Wọ́n ti di àjàgà sí mi ní ọrùn, Ó sú mi láti fi ara dà wọ́n.
Ngoro yakwa nĩĩthũire ciathĩ cianyu cia Karũgamo ka Mweri, o na ciathĩ iria njathane. Maũndũ macio matuĩkĩte mũrigo harĩ niĩ, nĩmanogetie.
15 Nígbà tí ẹ bá tẹ́ ọwọ́ yín sókè ni àdúrà, Èmi yóò fi ojú mi pamọ́ fún un yín, kódà bí ẹ bá gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àdúrà, Èmi kò ni tẹ́tí sí i. “Ọwọ́ yín kún fún ẹ̀jẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa mwambararia moko manyu na igũrũ mũkĩhooya, nĩndĩrĩmũhithaga maitho makwa ndikamuone; o na mũngĩhooya mahooya maingĩ ndirĩmũiguaga. Nĩgũkorwo moko manyu maiyũrĩtwo nĩ thakame;
16 “Wẹ̀ kí ẹ sì jẹ́ kí ara yín mọ́. Ẹ mú ìwà ibi yín kúrò níwájú mi! Dáwọ́ àìṣedéédéé dúró,
mwĩthambei mwĩtherie. Eheriai ciĩko cianyu njũru maitho-inĩ makwa! Tigai gwĩka maũndũ mooru,
17 kọ́ láti ṣe rere! Wá ìdájọ́ òtítọ́, tu àwọn tí a ń pọ́n lójú nínú. Ṣàtìlẹyìn fún ẹ̀tọ́ aláìní baba, gbà ẹjọ́ opó rò.
mwĩrutei gwĩkaga wega! Thingatagai ciira wa kĩhooto, na mũkoomĩrĩria arĩa ahinyĩrĩrie. Tuagai ciira wa ciana cia ngoriai na kĩhooto, na mũthaithanagĩrĩre mũtumia wa ndigwa.”
18 “Ẹ wá ní ìsinsin yìí, ẹ jẹ́ kí a jọ ṣàṣàrò,” ni Olúwa wí. “Bí ẹ̀ṣẹ̀ yín bá rí bí osùn, wọn ó sì funfun bí i yìnyín, bí wọn bá sì pọ́n bí ẹ̀jẹ̀, wọn ó sì dàbí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Jehova ekuuga atĩrĩ, “Ũkai tũciire. O na mehia manyu mangĩkorwo matunĩhĩte ta gakarakũ-rĩ, nĩmagathera o ta ira; o na maatuĩka matunĩhĩte ta thakame, nĩmakerũha o ta guoya wa ngʼondu.
19 Tí ẹ̀yin bá fẹ́, tí ẹ sì gbọ́rọ̀, ẹ̀yin yóò sì jẹ ojúlówó adùn ilẹ̀ náà.
Mũngĩnjigua na mũnjathĩkĩre, nĩ mũrĩrĩĩaga indo iria njega mũno cia bũrũri;
20 Ṣùgbọ́n tí ẹ bá kọ̀ tí ẹ sì ṣọ̀tẹ̀, idà ni a ó fi pa yín run.” Nítorí ẹnu Olúwa la ti sọ ọ́.
no mũngĩrema na mũrege gwathĩka, mũkaaniinwo na rũhiũ rwa njora.” Nĩgũkorwo nĩ kanua ka Jehova koigĩte ũguo.
21 Wo bí ìlú òtítọ́ ṣe di àgbèrè! Ó ti kún fún ìdájọ́ òtítọ́ nígbà kan rí, òdodo ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí, ṣùgbọ́n báyìí àwọn apànìyàn!
Hĩ! Kaĩ itũũra inene rĩrĩa rĩĩhokeku nĩrĩtuĩkĩte ta mũmaraya-ĩ! Hĩndĩ ĩmwe rĩaiyũrĩte ũtuanĩri ciira wa kĩhooto; ũthingu nĩguo watũũraga thĩinĩ warĩo, no rĩu nĩ oragani matũũraga kuo!
22 Fàdákà rẹ ti di ìpẹ́pẹ́, ààyò wáìnì rẹ la ti bu omi là.
Betha yanyu ĩtuĩkĩte gĩko, ndibei yanyu ĩrĩa njega mũno ĩgatukanio na maaĩ.
23 Ọlọ̀tẹ̀ ni àwọn aláṣẹ yín, akẹgbẹ́ àwọn olè, gbogbo wọn ló fẹ́ràn àbẹ̀tẹ́lẹ̀ wọ́n sì ń wá ẹ̀bùn kiri. Wọ́n kì í ṣàtìlẹyìn fún ẹ̀tọ́ aláìní baba, ẹjọ́ opó kì í sì í dé iwájú wọn.
Andũ anyu arĩa mamwathaga nĩ kũrema maremete, magatuĩka a thiritũ ya aici; othe nĩmendete mahaki, nao mahanyũkanagia na indo cia kũheo. Maticiiragĩra ciana cia ngoriai na kĩhooto; na matithikagĩrĩria ciira wa mũtumia wa ndigwa.
24 Nítorí náà ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, alágbára kan ṣoṣo tí Israẹli sọ wí pé: “Á à! Èmi yóò ní ìfọ̀kànbalẹ̀ lórí àwọn ọ̀tá mi n ó sì gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá mi.
Nĩ ũndũ ũcio, Mwathani, Jehova Mwene-Hinya-Wothe, O we Mwene Hinya wa Isiraeli, ekuuga atĩrĩ, “Hĩ! Nĩngaitĩrĩria amuku akwa mangʼũrĩ makwa, na ndĩĩrĩhĩrie harĩ thũ ciakwa.
25 Èmi yóò pa ọwọ́ mi dà sí ọ, èmi ó sì ku ìpẹ́pẹ́ rẹ dànù, n ó sì mú gbogbo ìdọ̀tí rẹ kúrò.
Nĩngagũũkĩrĩra na guoko gwakwa; ngagũtheria gĩko gĩaku gĩthire biũ, na maũndũ maku mothe marĩa matarĩ matheru ndĩmatherie.
26 Èmi yóò mú àwọn adájọ́ rẹ bọ̀ sí ipò gẹ́gẹ́ bí i ti àtijọ́, àti àwọn olùdámọ̀ràn rẹ̀ bí i ti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀. Lẹ́yìn náà ni a ó pè ọ ní ìlú òdodo, ìlú òtítọ́.”
Aciirithania aku ngaatũma matuĩke o ta ũrĩa maatariĩ matukũ-inĩ ma tene, na aheani kĩrĩra aku o ta ũrĩa maatariĩ kĩambĩrĩria-inĩ. Thuutha ũcio ũgeetagwo Itũũra Inene rĩa Ũthingu, o na Itũũra Inene Rĩĩhokeku.”
27 A ó fi ìdájọ́ òtítọ́ ra Sioni padà, àti àwọn tí ó ronúpìwàdà pẹ̀lú òdodo.
Itũũra rĩa Zayuni rĩgaakũũrwo na ciira wa kĩhooto, nao andũ a rĩo arĩa merirĩte makũũrwo na ũthingu.
28 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ̀tẹ̀ àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni a ó parun. Àwọn tí ó bá sì kọ Olúwa sílẹ̀ ni yóò ṣègbé.
No andũ arĩa aremi na arĩa ehia makaaniinwo hamwe, nao arĩa matiganagĩria Jehova nĩmagathira biũ.
29 “Ojú yóò tì yín nítorí igi óákù mímọ́ èyí tí ẹ ní inú dídùn sí, a ó kàn yín lábùkù nítorí àwọn ọgbà yìí tí ẹ ti yàn fúnra yín.
“Nĩmũgaconoka nĩ ũndũ wa mĩgandi ĩyo mĩamũre mũtũire mũkenagĩra; nĩmũkaigua thoni nĩ ũndũ wa mĩgũnda ĩyo mwĩthuurĩire.
30 Ẹ ó sì dàbí igi óákù tí ewé rẹ̀ ti rọ, bí ọgbà tí kò ní omi.
Mũgaatuĩka ta mũgandi ũrahooha mathangũ, mũtuĩke ta mũgũnda ũtarĩ maaĩ.
31 Alágbára ọkùnrin náà yóò sì dàbí ohun ìdáná, iṣẹ́ rẹ̀ bí ẹ̀ṣẹ́-iná, àwọn méjèèjì ni yóò jóná papọ̀, láìsí ẹni tí yóò lè pa iná yìí.”
Mũndũ ũrĩa ũrĩ hinya agaatuĩka maragara, naguo wĩra wake ũtuĩke thandĩ; we na wĩra wake nĩmakahĩa hamwe, haage mũndũ wa kũhoria mwaki ũcio.”

< Isaiah 1 >