< Isaiah 1 >

1 Ìran sí Juda àti Jerusalẹmu èyí tí Isaiah ọmọ Amosi rí ní àsìkò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah àwọn ọba Juda.
Judah manghai rhoek Uzziah, Jotham, Ahaz neh Hezekiah tue vaengah Judah neh Jerusalem ham Amoz capa Isaiah loh a mangthui a hmuh.
2 Gbọ́ ẹ̀yin ọ̀run! Fi etí sílẹ̀, ìwọ ayé! Nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀: “Mo tọ́ àwọn ọmọ dàgbà, ṣùgbọ́n wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi.
Vaan rhoek loh ya uh lamtah diklai long khaw hnakaeng saeh. BOEIPA loh, “Ka ca rhoek he ka pantai sak tih ka pomsang coeng dae, amamih long ni kai taengah boe a koek uh.
3 Màlúù mọ olówó rẹ̀, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sì mọ ibùjẹ olówó rẹ̀, ṣùgbọ́n Israẹli kò mọ̀, òye kò yé àwọn ènìyàn mi.”
Vaito loh amah aka lai te a ming tih laak long a boei kah kongduk te a hmat. Ka pilnam Israel loh ming voel pawt tih yakming voel pawh.
4 Á à! Orílẹ̀-èdè ẹlẹ́ṣẹ̀, àwọn ènìyàn tí ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ń pa lẹ́rù, ìran àwọn aṣebi, àwọn ọmọ tó ti di aṣèbàjẹ́! Wọn ti kọ Olúwa sílẹ̀ wọn ti gan Ẹni Mímọ́ Israẹli, wọn sì ti kẹ̀yìn sí i.
A nunae, namtom laihmuh aih, thaesainah loh a payawk pilnam, thaehuet kah tiingan, poci kah a ca rhoek, BOEIPA te a hnoo uh tih Israel kah aka cim te a tlaitlaek dongah a hnuk la kholong uh coeng.
5 Èéṣe tí a ó fi tún lù yín mọ́? Èéṣe tí ẹ ò dẹ́kun ọ̀tẹ̀ ṣíṣe? Gbogbo orí yín jẹ́ kìkì ọgbẹ́, gbogbo ọkàn yín sì ti pòruurù.
Balae tih koep kang ngawn eh? Koeknah te na koei uh tih na lu te a tlohtat kak la, na thinko boeih khaw hal coeng.
6 Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín dé àtàrí yín kò sí àlàáfíà rárá, àyàfi ọgbẹ́ òun ìfarapa àti ojú egbò, tí a kò nù kúrò tàbí kí á dì tàbí kí a kùn ún ní òróró.
A kho khopha lamloh a lu due hlang la om voel pawh. A tloh neh a hma, hmasoe a haeng khaw yawt uh pawt tih poi uh pawh, situi nen khaw yaih sak pawh.
7 Orílẹ̀-èdè yín dahoro, a dáná sun àwọn ìlú yín, oko yín ni àwọn àjèjì ti jẹ run lójú ara yín náà, ni gbogbo rẹ̀ ṣòfò bí èyí tí àwọn àjèjì borí rẹ̀.
Na khohmuen te khopong la om coeng. Na khopuei rhoek hmai neh a hoeh coeng. Na diklai khaw na mikhmuh ah kholong loh han caak coeng. Te dongah khopong neh imrhong bangla a kholong boeih coeng.
8 Ọmọbìnrin Sioni ni a fi sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àtíbàbà nínú ọgbà àjàrà, gẹ́gẹ́ bí abà nínú oko ẹ̀gúnsí, àti bí ìlú tí a dó tì.
Zion nu misur dum kah poca bangla, uitang lo kah tlak bangla, khopuei a dum bangla hoei sut coeng,” a ti.
9 Àyàfi bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun bá ṣẹ́ díẹ̀ kù fún wà, a ò bá ti rí bí Sodomu, a ò bá sì ti dàbí Gomorra.
Caempuei BOEIPA loh mamih he rhaengnaeng la bet n'hlun pawt koinih Sodom bangla ng'om vetih Gomorrah bangla n'lutlat uh ni.
10 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin aláṣẹ Sodomu, tẹ́tí sí òfin Ọlọ́run wa, ẹ̀yin ènìyàn Gomorra!
Sodom rhalboei rhoek BOEIPA olka te ya uh lah. Gomorrah pilnam loh mamih Pathen kah olkhueng te hnakaeng thil lah.
11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín kín ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín jásí fún mi?” ni Olúwa wí. “Mo ti ní ànító àti àníṣẹ́kù ẹbọ sísun ti àgbò àti ọ̀rá ẹran àbọ́pa, Èmi kò ní inú dídùn nínú ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù, ti àgùntàn àti ti òbúkọ.
Nangmih hmueih aka khawk te kai ham ee te? BOEIPA loh, “Hmueihhlutnah tutal, puetsuet kah a tha, vaito thii, tuca neh kikong loh n'lawt tih ka ngaih moenih.
12 Nígbà tí ẹ wá farahàn níwájú mi, ta ni ó béèrè èyí lọ́wọ́ yín, gìrì gìrì ẹsẹ̀ nínú àgbàlá mi?
Kai mikhmuh ah phoe hamla na pawk uh vaengah na kut dongkah he unim aka suk tih kai kah vongup nan taelh uh.
13 Ẹ má mú ọrẹ asán wá mọ́! Ìríra ni tùràrí yín jásí fún mi, oṣù tuntun àti ọjọ́ ìsinmi àti àwọn àpéjọ, Èmi kò lè faradà á, ẹ̀ṣẹ̀ ni àpéjọ yín wọ̀nyí.
A Poeyoek la khocang nang khuen neh ng'koei boeh. Bo-ul khaw kai ham tueilaehkoi ni. Hlasae neh Sabbath ah tingtunnah a khue te khaw, boethae neh pahong khaw ka ueh thai pawh.
14 Ayẹyẹ oṣù tuntun yín àti àjọ̀dún tí a yàn, ni ọkàn mi kórìíra. Wọ́n ti di àjàgà sí mi ní ọrùn, Ó sú mi láti fi ara dà wọ́n.
Nangmih kah hlasae neh na tingtunnah te ka hinglu loh a hmuhuet tih, kai ham laipuei la a poeh dongah ka phueih ka ngak.
15 Nígbà tí ẹ bá tẹ́ ọwọ́ yín sókè ni àdúrà, Èmi yóò fi ojú mi pamọ́ fún un yín, kódà bí ẹ bá gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àdúrà, Èmi kò ni tẹ́tí sí i. “Ọwọ́ yín kún fún ẹ̀jẹ̀.
Na kut na phuel uh vaengah nangmih taeng lamloh ka mik vik ka him ni. Thangthuinah loh puh cakhaw na kut ah hlang thii a bae dongah ka hnatun mahpawh.
16 “Wẹ̀ kí ẹ sì jẹ́ kí ara yín mọ́. Ẹ mú ìwà ibi yín kúrò níwájú mi! Dáwọ́ àìṣedéédéé dúró,
Sil uh lamtah cim uh. Na khoboe thaenah khaw khoe uh lamtah ka mikhmuh lamkah thaehuet te toeng uh.
17 kọ́ láti ṣe rere! Wá ìdájọ́ òtítọ́, tu àwọn tí a ń pọ́n lójú nínú. Ṣàtìlẹyìn fún ẹ̀tọ́ aláìní baba, gbà ẹjọ́ opó rò.
Voelphoeng hamla cang uh. Tiktamnah te tlap. Hlang hnaepnah te toel uh. Cadah te rhuun uh lamtah, nuhmai ham te oelh pah.
18 “Ẹ wá ní ìsinsin yìí, ẹ jẹ́ kí a jọ ṣàṣàrò,” ni Olúwa wí. “Bí ẹ̀ṣẹ̀ yín bá rí bí osùn, wọn ó sì funfun bí i yìnyín, bí wọn bá sì pọ́n bí ẹ̀jẹ̀, wọn ó sì dàbí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Ha mop uh lamtah tluung uh thae pawn sih. BOEIPA loh, “Nangmih kah tholhnah te lingdik bangla om cakhaw vuel bangla om ni. Talam bangla thimyum cakhaw tumul bangla bok ni,” a ti.
19 Tí ẹ̀yin bá fẹ́, tí ẹ sì gbọ́rọ̀, ẹ̀yin yóò sì jẹ ojúlówó adùn ilẹ̀ náà.
Na huem uh tih na hnatun uh atah khohmuen kah a thennah te na caak uh ni.
20 Ṣùgbọ́n tí ẹ bá kọ̀ tí ẹ sì ṣọ̀tẹ̀, idà ni a ó fi pa yín run.” Nítorí ẹnu Olúwa la ti sọ ọ́.
Tedae na aal tih na koek uh atah BOEIPA ol a thui coeng dongah cunghang na yook uh ni.
21 Wo bí ìlú òtítọ́ ṣe di àgbèrè! Ó ti kún fún ìdájọ́ òtítọ́ nígbà kan rí, òdodo ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí, ṣùgbọ́n báyìí àwọn apànìyàn!
Khorha cakrhuet, tiktamnah neh aka bae te balae tih pumyoi la poeh. Duengnah khaw a khuiah rhaehrhong dae hlang a ngawn coeng.
22 Fàdákà rẹ ti di ìpẹ́pẹ́, ààyò wáìnì rẹ la ti bu omi là.
Nangmih kah ngun te aek la poeh tih na yuhuem khaw tui neh poek uh coeng.
23 Ọlọ̀tẹ̀ ni àwọn aláṣẹ yín, akẹgbẹ́ àwọn olè, gbogbo wọn ló fẹ́ràn àbẹ̀tẹ́lẹ̀ wọ́n sì ń wá ẹ̀bùn kiri. Wọ́n kì í ṣàtìlẹyìn fún ẹ̀tọ́ aláìní baba, ẹjọ́ opó kì í sì í dé iwájú wọn.
Na mangpa rhoek a thinthah uh tih a pum la hlanghuen neh hui uh thae. Kapbaih a lungnah tih kapbaih ni a hloem. Cadah te laitloek pa uh pawt tih nuhmai kah tuituknah khaw amamih taengah phoe puei pawh.
24 Nítorí náà ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, alágbára kan ṣoṣo tí Israẹli sọ wí pé: “Á à! Èmi yóò ní ìfọ̀kànbalẹ̀ lórí àwọn ọ̀tá mi n ó sì gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá mi.
Te dongah caempuei Boeipa, Yahovah, Israel kah samrhang olphong loh, “A nunae, Ka thunkha rhoek soah phu ka loh daengah ni ka rhal rhoek taengah dam ka ti pueng eh.
25 Èmi yóò pa ọwọ́ mi dà sí ọ, èmi ó sì ku ìpẹ́pẹ́ rẹ dànù, n ó sì mú gbogbo ìdọ̀tí rẹ kúrò.
Nangmih taengah ka kut kan thuung ni. Te vaengah na khen te lunghuem neh ka dung vetih na ti boeih ka khong ni.
26 Èmi yóò mú àwọn adájọ́ rẹ bọ̀ sí ipò gẹ́gẹ́ bí i ti àtijọ́, àti àwọn olùdámọ̀ràn rẹ̀ bí i ti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀. Lẹ́yìn náà ni a ó pè ọ ní ìlú òdodo, ìlú òtítọ́.”
Na laitloek te hnukbuet kah bangla, na olrhoep khaw lamhma kah bangla kan thuung ni. Tahae lamkah tah nang te duengnah khopuei, uepom khorha la ng'khue ni.
27 A ó fi ìdájọ́ òtítọ́ ra Sioni padà, àti àwọn tí ó ronúpìwàdà pẹ̀lú òdodo.
Zion te tiktamnah neh a lat vetih duengnah neh ha mael ni.
28 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ̀tẹ̀ àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni a ó parun. Àwọn tí ó bá sì kọ Olúwa sílẹ̀ ni yóò ṣègbé.
Tedae boekoek rhoek neh BOEIPA aka hnoo hlangtholh rhoek tah pocinah loh rhenten a khah ni.
29 “Ojú yóò tì yín nítorí igi óákù mímọ́ èyí tí ẹ ní inú dídùn sí, a ó kàn yín lábùkù nítorí àwọn ọgbà yìí tí ẹ ti yàn fúnra yín.
Thingnu na nai uh te yak vetih, dum na tuek uh dongah khaw na hmai tal uh ni.
30 Ẹ ó sì dàbí igi óákù tí ewé rẹ̀ ti rọ, bí ọgbà tí kò ní omi.
Rhokael te a hnah a hoo bangla, tui loh dum te a kaktah bangla na om uh ni.
31 Alágbára ọkùnrin náà yóò sì dàbí ohun ìdáná, iṣẹ́ rẹ̀ bí ẹ̀ṣẹ́-iná, àwọn méjèèjì ni yóò jóná papọ̀, láìsí ẹni tí yóò lè pa iná yìí.”
Aka tlung khaw malpawt la, a bisai te hmaidi la poeh ni. Te vaengah a boktlap la rhenten a dom vetih thih uh mahpawh.

< Isaiah 1 >