< Isaiah 9 >
1 Síbẹ̀síbẹ̀, kò ní sí ìpòrúru kankan mọ́ fún àwọn tí ó wà nínú ìbànújẹ́. Nígbà kan rí ó rẹ ilẹ̀ Sebuluni sílẹ̀ àti ilẹ̀ Naftali pẹ̀lú, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ iwájú, yóò bu ọ̀wọ̀ fún Galili ti àwọn aláìkọlà, ní ọ̀nà Òkun, ní ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ Jordani.
Kodwa umnyama kawuyikuba njengenkathazo yalo; njengesikhathini samandulo wakwenza kwaba lula elizweni lakoZebuluni lelizweni lakoNafithali; kodwa emva kwalokhu wakwenza kwaba nzima ngendlela yolwandle, phetsheya kweJordani, eGalili lezizwe.
2 Àwọn ènìyàn tí ń rìn nínú òkùnkùn ti rí ìmọ́lẹ̀ ńlá; lórí àwọn tí ń gbé nínú ilẹ̀ òjìji ikú, ní ara wọn ni ìmọ́lẹ̀ mọ́ sí.
Abantu ababehamba emnyameni babonile ukukhanya okukhulu; ababehlala elizweni lethunzi lokufa, ukukhanya kubakhanyisele.
3 Ìwọ ti sọ orílẹ̀-èdè di ńlá; wọ́n sì yọ̀ níwájú rẹ gẹ́gẹ́ bí àwọn ènìyàn ti í yọ ayọ̀ ìkórè, gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ti í yọ̀ nígbà tí à ń pín ìkógun.
Wandisile isizwe, wakhulisa intokozo yaso; bayathokoza phambi kwakho njengentokozo ekuvuneni, njengoba bethokoza ekwehlukaniselaneni kwabo impango.
4 Nítorí gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí a ṣẹ́gun Midiani, ìwọ ti fọ́ ọ túútúú àjàgà ti ń pa wọ́n lẹ́rù, ọ̀pá tí ó dábùú èjìká wọn, ọ̀gọ aninilára wọn.
Ngoba wephulile ijogwe lomthwalo waso, loswazi lwehlombe laso, intonga yomcindezeli waso, njengasosukwini lukaMidiyani.
5 Gbogbo bàtà jagunjagun tí a ti lò lójú ogun àti gbogbo ẹ̀wù tí a yí nínú ẹ̀jẹ̀, ni yóò wà fún ìjóná, àti ohun èlò iná dídá.
Ngoba wonke umsindo wempi usenhlokomeni, lesigqoko sigiqwe egazini; njalo kuzakuba ngesokutshiswa, kube zinkuni zomlilo.
6 Nítorí a bí ọmọ kan fún wa, a fi ọmọkùnrin kan fún wa, ìjọba yóò sì wà ní èjìká rẹ̀. A ó sì máa pè é ní Ìyanu Olùdámọ̀ràn, Ọlọ́run Alágbára, Baba ayérayé, Ọmọ ọba aládé Àlàáfíà.
Ngoba sizalelwe umntwana, sinikwe indodana; lombuso uzakuba sehlombe layo, lebizo lakhe lizathiwa: OMangalisayo, uMeluleki, uNkulunkulu olamandla, uBaba wephakade, iNkosana yokuthula.
7 Ní ti gbígbòòrò Ìjọba rẹ̀ àti àlàáfíà rẹ̀ ni kì yóò ní ìpẹ̀kun. Yóò jẹ ọba lórí ìtẹ́ Dafidi àti lórí ẹ̀kún un rẹ̀ gbogbo, nípa ìfìdímúlẹ̀ àti ìgbéró rẹ̀, pẹ̀lú òtítọ́ àti òdodo láti ìgbà náà lọ àti títí láéláé. Ìtara Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni yóò mú èyí ṣẹ.
Ukwanda kombuso lokuthula kakuyikuphela, phezu kwesihlalo sobukhosi sikaDavida laphezu kombuso wakhe, ukuwumisa, lokuwuqinisa ngesahlulelo langokulunga, kusukela khathesi kuze kube nininini. Ukutshiseka kweNkosi yamabandla kuzakwenza lokhu.
8 Olúwa ti dojú iṣẹ́ kan kọ Jakọbu; yóò sì wá sórí Israẹli.
INkosi ithumele ilizwi koJakobe, lawela koIsrayeli.
9 Gbogbo ènìyàn ni yóò sì mọ̀ ọ́n— Efraimu àti gbogbo olùgbé Samaria— tí ó sọ pẹ̀lú ìgbéraga àti gààrù àyà pé.
Labo bonke abantu bazakwazi, uEfrayimi lomhlali weSamariya, ngokuzigqaja langokuzikhukhumeza kwenhliziyo, besithi:
10 Àwọn bíríkì ti wó lulẹ̀ ṣùgbọ́n a ó tún un kọ́ pẹ̀lú òkúta dídán, a ti gé àwọn igi sikamore lulẹ̀ ṣùgbọ́n igi kedari ní a ó fi dípò wọn.
Izitina ziwile, kodwa sizakwakha ngamatshe abaziweyo; imikhiwa yesikhamore iganyuliwe, kodwa sizayiguqula ibe yimisedari.
11 Ṣùgbọ́n Olúwa fún àwọn ọ̀tá Resini ní agbára láti dojúkọ wọ́n ó sì ti rú àwọn ọ̀tá wọn sókè.
Ngakho iNkosi izaphakamisa abacindezeli bakaRezini phezu kwakhe, itshotshozele izitha zakhe;
12 Àwọn ará Aramu láti ìlà-oòrùn àti Filistini láti ìwọ̀-oòrùn. Wọ́n sì fi gbogbo ẹnu jẹ Israẹli run. Ní gbogbo èyí ìbínú rẹ̀ kò yí kúrò ṣùgbọ́n ọwọ́ rẹ̀ nà jáde síbẹ̀.
amaSiriya ngaphambili lamaFilisti ngemuva, azakudla uIsrayeli ngomlomo wonke. Kukho konke lokhu intukuthelo yayo kayiphenduki, kodwa isandla sayo silokhu seluliwe.
13 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà kò tí ì yípadà sí ẹni náà tí ó lù wọ́n bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kò wá Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Ngoba abantu kabaphendukeli kulowo owabatshayayo, futhi kabayidingi iNkosi yamabandla.
14 Nítorí náà ni Olúwa yóò ṣe ké àti orí àti ìrù kúrò ní Israẹli, àti ọ̀wá ọ̀pẹ àti koríko odò ní ọjọ́ kan ṣoṣo,
Ngakho iNkosi izaquma kusuke koIsrayeli inhloko lomsila, ugatsha lomhlanga, ngasuku lunye.
15 àwọn àgbàgbà, àti àwọn gbajúmọ̀ ní orí, àwọn wòlíì tí ń kọ́ni ní irọ́ ni ìrù.
Omdala lowemukelwa ngobuso, uyinhloko, kodwa umprofethi ofundisa amanga, ungumsila.
16 Àwọn tí ó ń tọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣì wọ́n lọ́nà, àwọn tí a sì tọ́ ni a ń sin sí ìparun.
Ngoba abakhokheli balababantu bayaduhisa, labakhokhelwa yibo bayaginywa.
17 Nítorí náà, Olúwa kì yóò dunnú sí àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin tàbí kí ó káàánú àwọn aláìní baba àti opó, nítorí pé gbogbo wọn jẹ́ ìkà àti aláìmọ Ọlọ́run, ibi ni ó ti ẹnu wọn jáde. Síbẹ̀, fún gbogbo èyí, ìbínú rẹ̀ kò yí kúrò ọwọ́ rẹ̀ sì wà ní gbígbéró.
Ngenxa yalokho iNkosi kayiyikuthokoza ngamajaha abo, kayiyikuba lasihawu ngezintandane zabo labafelokazi babo; ngoba bonke bangabazenzisi labenzi bobubi, lomlomo wonke ukhuluma ubuthutha. Kukho konke lokhu intukuthelo yayo kayiphenduki, kodwa isandla sayo silokhu seluliwe.
18 Nítòótọ́ ìwà búburú ń jóni bí iná, yóò jó ẹ̀wọ̀n àti ẹ̀gún run, yóò sì rán nínú pàǹtí igbó, tó bẹ́ẹ̀ tí yóò fi gòkè lọ bí ọ̀wọ́n èéfín ti í gòkè.
Ngoba inkohlakalo itshisa njengomlilo; izakudla ameva lokhula oluhlabayo, ithungele izixuku zehlathi, ziziphakamise njengokuphakama kwentuthu.
19 Nípasẹ̀ ìbínú Olúwa àwọn ọmọ-ogun ilẹ̀ náà yóò di gbígbẹ àwọn ènìyàn yóò sì di ohun ìdáná, ẹnìkan kì yóò sì dá arákùnrin rẹ̀ sí.
Ngolaka lweNkosi yamabandla ilizwe liyafiphazwa, labantu bazakuba njengokudla komlilo; umuntu kayikuyekela umfowabo.
20 Ní apá ọ̀tún wọn yóò jẹrun, síbẹ̀ ebi yóò sì máa pa wọ́n, ní apá òsì, wọn yóò jẹ, ṣùgbọ́n, kò ní tẹ́ wọn lọ́rùn. Ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò sì máa jẹ ẹran-ara apá rẹ̀.
Njalo uzahluthuna ngakwesokunene, kodwa alambe; adle ngakwesokhohlo, kodwa angasuthi; ngulowo lalowo adle inyama yengalo yakhe;
21 Manase yóò máa jẹ Efraimu, nígbà tí Efraimu yóò jẹ Manase wọn yóò parapọ̀ dojúkọ Juda. Síbẹ̀síbẹ̀, ìbínú un rẹ̀ kò yí kúrò Ọwọ́ọ rẹ̀ sì wà ní gbígbéró.
uManase uEfrayimi, loEfrayimi uManase; bazamelana loJuda kanyekanye. Kukho konke lokhu intukuthelo yayo kayiphenduki, kodwa isandla sayo silokhu seluliwe.