< Isaiah 65 >

1 “Èmi fi ara mi hàn fún àwọn tí kò béèrè fún mi; àwọn tí kò wá mi ni wọ́n rí mi. Sí àwọn orílẹ̀-èdè tí kò pe orúkọ mi, ni èmi wí pé, ‘Èmi nìyìí, Èmi nìyìí.’
LEUM GOD El fahk, “Nga tuh akola in topuk pre lun mwet luk, a elos tiana pre. Nga tuh akola elos in koneyuyak, a elos tiana srike in sukyu. Mutanfahl se inge tiana pre nu sik, nga finne akola pacl nukewa in topkolos, ‘Nga pa inge; nga fah kasrekowos.’
2 Gbogbo ọjọ́ ni mo ti nawọ́ mi síta sí àwọn ènìyàn ọlọ́rùn líle, tí wọn ń rìn lọ́nà tí kò dára, tí wọ́n sì gbára lé èrò ara wọn
Nga akola pacl nukewa in paing mwet luk, su likkekelana in oru ma sutuu ac fahsr ke inkanek lalos sifacna.
3 àwọn ènìyàn tí wọ́n bí mi nínú nígbà gbogbo lójú ara mi gan an, wọ́n ń rú ẹbọ nínú ọgbà wọ́n sì ń sun tùràrí lórí i pẹpẹ bíríkì;
Elos tiana mwekin in akkasrkusrakyeyu pacl nukewa. Elos oru mwe kisa nu ke ma sruloala in ima oal lalos, ac furreak mwe keng fin loang lun mwet pegan.
4 wọ́n ń jókòó láàrín ibojì wọ́n sì ń lo òru wọn nínú ìṣọ́ ìkọ̀kọ̀; tí wọ́n ń jẹ ẹran ẹlẹ́dẹ̀, tí ìkòkò ọbẹ̀ wọn kún fún ẹran àìmọ́;
Ke fong uh elos som nu in luf ac nu ke kulyuk, in lolngok yurin ngunin mwet misa. Elos kang ikwen pig ac nim sronin ikwa ma kisakinyuk ke ouiya lun mwet pegan.
5 tí ó wí pé, ‘Ẹ sún mẹ́yìn; ẹ má wá sọ́dọ̀ mi, nítorí mo ti jẹ́ mímọ́ jù fún un yín!’ Àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ jẹ́ èéfín nínú ihò imú mi iná tí ń fi gbogbo ọjọ́ jó.
Na elos fahk nu sin mwet ngia, ‘Nimet kaluku nu yorosr. Kut mutallana, ac sufal kowos in pusral kut.’ Nga koflana muteng kain mwet ouingan — kasrkusrak luk kaclos oana sie e na ngeng ma tia ku in kunla.
6 “Kíyèsi i, a ti kọ ọ́ síwájú mi, Èmi kì yóò dákẹ́, ṣùgbọ́n èmi yóò san án padà lẹ́kùnrẹ́rẹ́; Èmi yóò san án padà sí àyà wọn
“Nga nunkala tari kalya ma fal nu selos, ac simla pac tari ma ac orek nu selos. Nga fah tia likinsai ma elos orala tari, a nga ac fah folokin nu selos
7 àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín àti tàwọn baba yín,” ni Olúwa wí. “Nítorí pé wọ́n sun ẹbọ ní orí òkè ńlá wọ́n sì ṣe ẹ̀gbin sí mi ní òkè kékeré, Èmi yóò wọ́n ọ́n sí itan wọn ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ẹ̀san ohun gbogbo tí wọ́n ṣe tẹ́lẹ̀.”
fal nu ke ma koluk lalos ac oayapa ma koluk lun mwet matu lalos. Elos esukak mwe keng fin inging uh ke nien alu lun mwet pegan, ac fahk kas koluk keik. Ouinge nga fah kaelos fal nu ke orekma koluk lalos.”
8 Báyìí ni Olúwa wí: “Gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí oje sì tún wà nínú àpólà àjàrà tí àwọn ènìyàn sì wí pé, ‘Má ṣe bà á jẹ́, nítorí ìbùkún ń bẹ nínú rẹ̀,’ bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣe nítorí ìránṣẹ́ mi; Èmi kì yóò pa gbogbo wọn run.
LEUM GOD El fahk, “Wangin mwet sisla ung in grape fon se, a elos ac srela ma wo kac in orekmakin nu ke wain. Ouinge nga fah tia pac kunausla mwet luk nukewa — nga ac molela mwet su kulansupweyu.
9 Èmi yóò mú ìrandíran wá láti ìdílé Jakọbu, àti láti Juda àwọn tí yóò jogún òkè ńlá mi wọ̀n-ọn-nì; àwọn àyànfẹ́ ènìyàn mi yóò jogún wọn, ibẹ̀ ni àwọn ìránṣẹ́ mi yóò sì gbé.
Nga ac fah akinsewowoye mwet Israel su ma in sruf lun Judah, ac fwilin tulik natulos fah usrui acn sik in eol uh. Mwet solla luk su kulansupweyu fah muta we.
10 Ṣaroni yóò di pápá oko fún ọ̀wọ́ ẹran, àti àfonífojì Akori yóò di ibi ìsinmi fún agbo ẹran, fún àwọn ènìyàn mi tí ó wá mi.
Elos fah alu nu sik, ac fah pwen sheep ac cow natulos nu insroan mah in acn Tupasrpasr lun Sharon layen nu roto, ac nu Infahlfal in Ongoiya layen nu kutulap.
11 “Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó kọ Olúwa sílẹ̀ tí ó sì gbàgbé òkè ńlá mímọ́ mi, tí ó tẹ́ tábìlì fún Gadi tí ẹ sì kún abọ́ pẹ̀lú ọtí wáìnì fún àtubọ̀tán,
“Tusruktu ac fah tia ouinge nu suwos su ngetla likiyu ac mulkunla Zion, eol mutal sik, ac alu nu sel Gad — god lun wo ouiya, ac nu sel Meni — god lun ongoiya.
12 Èmi yóò yà ọ́ sọ́tọ̀ fún idà, àti pé ẹ̀yin yóò bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀ fún àwọn tí a pa; nítorí mo pè, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò dáhùn. Mo sọ̀rọ̀ ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò tẹ́tí sílẹ̀. Ẹ̀yin ṣe búburú ní ojú mi ẹ sì yan ohun tí ó bà mí lọ́kàn jẹ́.”
Ac fah koluk ouiya nu suwos ac kowos ac anwuki ke cutlass, mweyen kowos tia topuk ke pacl nga pangon kowos, ku porongo ke pacl nga kaskas. Kowos sulela in seakosyu ac oru ma koluk.
13 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò jẹun; ṣùgbọ́n ebi yóò máa pa ẹ̀yin, àwọn ìránṣẹ́ mi yóò mu, ṣùgbọ́n òǹgbẹ yóò máa gbẹ ẹ̀yin; àwọn ìránṣẹ́ mi yóò ṣe àjọyọ̀, ṣùgbọ́n a ó dójútì yin.
Ouinge nga fahk nu suwos lah elos su alu nu sik ac akosyu fah pukanten mwe mongo nalos ac mwe nim nimalos, a kowos fah masrinsral ac malu. Elos ac fah engan, a kowos ac fah akmwekinyeyuk.
14 Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò kọrin láti inú ayọ̀ ọkàn wọn wá, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò kígbe sókè láti inú ìrora ọkàn yín àti ìpohùnréré ní ìròbìnújẹ́ ọkàn.
Elos ac fah on ke engan, a kowos ac tung ke asor ac toasr.
15 Ẹ̀yin yóò fi orúkọ yín sílẹ̀ fún àwọn àyànfẹ́ mi gẹ́gẹ́ bí ègún; Olúwa Olódùmarè yóò sì pa yín, ṣùgbọ́n fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ni òun yóò fún ní orúkọ mìíràn.
Inewos fah sie kas in selnga lun mwet solla luk. Nga, LEUM GOD Fulatlana, fah lela in anwuki kowos. Tusruktu nga fah sang sie ine sasu nu selos su akosyu.
16 Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbàdúrà ìbùkún ní ilẹ̀ náà yóò ṣe é nípasẹ̀ Ọlọ́run òtítọ́; Ẹni tí ó bá búra ní ilẹ̀ náà yóò búra nípasẹ̀ Ọlọ́run òtítọ́. Nítorí ìyọnu àtijọ́ yóò di ìgbàgbé yóò sì fi ara sin kúrò lójú mi.
Kutena mwet in facl se inge su siyuk in akinsewowoyeyuk el, fah siyuk mwe insewowo sin God lun ma pwaye. Kutena mwet su orala kas in fulahk ku lal, fah oru ke Inen God lun ma pwaye. Ma koluk nukewa ke pacl somla ac fah wanginla ac mulkinyukla.”
17 “Kíyèsi i, Èmi yóò dá àwọn ọ̀run tuntun àti ayé tuntun. A kì yóò rántí ohun àtẹ̀yìnwá mọ́, tàbí kí wọn wá sí ọkàn.
LEUM GOD El fahk, “Nga orala kusrao sasu ac sie fahlu sasu. Ma meet ah ac fah mulkinyukla.
18 Ṣùgbọ́n ẹ yọ̀ kí inú yín dùn títí láé nínú ohun tí èmi yóò dá, nítorí èmi yóò dá Jerusalẹmu láti jẹ́ ohun ìdùnnú àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ohun ayọ̀.
Kowos in engan ac insewowo nwe tok ke ma nga oru inge. Jerusalem sasu ma nga ac oru ac fah sessesla ke engan, ac mwet we ac fah insewowo.
19 Èmi yóò ṣe àjọyọ̀ lórí Jerusalẹmu n ó sì ní inú dídùn nínú àwọn ènìyàn mi; ariwo ẹkún àti igbe ni a kì yóò gbọ́ nínú rẹ̀ mọ́.
Nga sifacna fah arulana enganak ke Jerusalem ac mwet we. Ac fah wangin pusren tung ac asor we.
20 “Títí láé a kì yóò gbọ́ nínú rẹ̀ ọmọ ọwọ́ tí yóò gbé fún ọjọ́ díẹ̀, tàbí àgbàlagbà tí kì yóò lo ọjọ́ ayé rẹ̀ tán; ẹni tí ó bá kú ní ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún ni a ó pè ní ọ̀dọ́mọdé; ẹni tí kò ba le pé ọgọ́rùn-ún kan ni a ó pè ní ẹni ìfibú.
Tulik srisrik ac fah tia sifilpa misa ke srakna fusr, ac mwet nukewa ac fah loes moul lalos. Elos su moul nwe sun yac siofok ac fah liyeyuk mu elos srakna fusr. Mwet se fin misa meet liki pacl sacn, ac fah sie akul lah nga kalyaelos.
21 Wọn yó ò kọ́ ilé, wọn yóò sì gbé nínú wọn wọn yóò gbin ọgbà àjàrà, wọn yóò sì jẹ èso wọn.
Elos fah musai lohm ac muta loac; elos ac yukwi ima in grape ac kang fahko kac.
22 Wọn kì yóò kọ́ ilé fún ẹlòmíràn láti gbé, tàbí kí wọn gbìn fún ẹlòmíràn láti jẹ. Nítorí gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ orí igi kan, bẹ́ẹ̀ ní ọjọ́ àwọn ènìyàn mi yóò rí; àwọn àyànfẹ́ mi yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ wọn fún ìgbà pípẹ́.
Elos ac tia musai na kutepacna mwet muta loac. Elos ac tia yukwi ima in grape na kutepacna mwet nim wain kac. Tuh mwet luk fah moul paht, oana lusen moul lun sak uh. Elos ac arulana engankin fokin orekma lalos.
23 Wọn kì yóò ṣe iṣẹ́ lásán, wọn kí yóò bímọ fún wàhálà; nítorí wọn yóò jẹ́ àwọn ènìyàn ti Olúwa bùkún fún, àwọn àti àwọn ìrandíran wọn pẹ̀lú wọn.
Orekma elos oru ac fah wo ouiya, ac tulik natulos fah tia sun ongoiya. Nga fah akinsewowoyalos ac fwilin tulik natulos nwe tok.
24 Kí wọn tó pè, èmi yóò dáhùn; nígbà tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, èmi yóò gbọ́.
Meet liki safla pre lalos nu sik, nga ac topuk mwe siyuk lalos.
25 Ìkookò àti ọ̀dọ́-àgùntàn yóò jẹun pọ̀, kìnnìún yóò sì jẹ koríko gẹ́gẹ́ bí akọ màlúù, ṣùgbọ́n erùpẹ̀ ni yóò jẹ́ oúnjẹ ejò. Wọn kì yóò pa ni lára tàbí pa ni run ní gbogbo òkè mímọ́ mi,” ni Olúwa wí.
Kosro wolf ac sheep fusr ac fah tukeni mongo. Lion uh ac fah mongo mah oana cow uh, ac wet pwasin ac fah tia sifil sensenkinyuk. Fineol Zion, eol mutal sik, ac fah wangin kutena mwe ngal ku ma koluk we.”

< Isaiah 65 >