< Isaiah 64 >

1 Ìwọ ìbá fa ọ̀run ya kí o sì sọ̀kalẹ̀ wá, tí àwọn òkè ńlá yóò fi wárìrì níwájú rẹ!
2 Gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí iná mú ẹ̀ka igi jó tí ó sì mú kí omi ó hó, sọ̀kalẹ̀ wá kí orúkọ rẹ le di mí mọ̀ fún àwọn ọ̀tá rẹ kí o sì jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè kí ó wárìrì níwájú rẹ!
Ah, Sen asmanlarni yirtiwétip, Yerge chüshken bolsang’idi! Taghlar bolsa yüzüng aldida érip kétetti! Mana mushundaq bolghanda tuturuqqa ot yaqqandek, Ot suni qaynatqandek, Sen namingni düshmenliringge ayan qilghan bolatting, Eller yüzüngdinla titrep kétetti!
3 Nítorí nígbà tí o bá ṣe àwọn ohun ẹ̀rù tí àwa kò nírètí, o sọ̀kalẹ̀ wá, àwọn òkè ńlá sì wárìrì níwájú rẹ̀.
Sen biz kütmigen dehshetlik ishlarni qilghan waqtingda, Sen chüshkeniding; Yüzüngdin taghlar rastla érip ketti!
4 Láti ìgbà àtijọ́ kò sí ẹni tí ó gbọ́ rí kò sí etí kan tí ó gbọ́ ọ, kò sí ojú tí ó tí ì rí Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn rẹ, tí ó máa ń ṣe nǹkan lórúkọ àwọn tí ó dúró dè é.
Sendin bashqa Özige telmürüp kütkenler üchün ishligüchi bir Xudani, Ademler ezeldin anglap baqmighan, Qulaqqa yétip baqmighan, Köz körüp baqmighandur!
5 Ìwọ a máa wá fún ìrànlọ́wọ́ àwọn tí wọn ń fi ayọ̀ ṣe ohun tó tọ́, tí ó rántí ọ̀nà rẹ. Ṣùgbọ́n nígbà tí a bẹ̀rẹ̀ sí dẹ́ṣẹ̀ sí wọn, inú bí ọ. Báwo ni a ó ṣe gbà wá là?
Sen heqqaniyliqni yürgüzüshni xursenlik dep bilgen ademning, Yeni yolliringda méngip, Séni séghin’ghanlarning hajitidin chiqquchi hemrahdursen; Biraq mana, Sen ghezepte boldung, Biz bolsaq gunahta bolduq; Undaq ishlar uzun boliwerdi; Emdi biz qutquzulamduq?
6 Gbogbo wa ti dàbí ẹnìkan tí ó jẹ́ aláìmọ́, gbogbo òdodo wa sì dàbí èkísà ẹlẹ́gbin; gbogbo wa kákò bí ewé, àti bí afẹ́fẹ́, ẹ̀ṣẹ̀ wa ti gbá wa lọ kúrò.
Emdi biz napak bir nersige oxshash bolduq, Qiliwatqan barliq «heqqaniyetlirimiz» bolsa bir ewret latisighila oxshaydu, xalas; Hemmimiz yopurmaqtek xazan bolup kettuq, Qebihliklirimiz shamaldek bizni uchurup tashliwetti.
7 Ẹnikẹ́ni kò pe orúkọ rẹ tàbí kí ó gbìyànjú láti dì ẹ́ mú; nítorí ìwọ ti fi ojú rẹ pamọ́ fún wa ó sì jẹ́ kí àwa ṣòfò dànù nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Séning namingni chaqirip nida qilghuchi, Iltipatingni tutushqa qozghalghuchi héch yoqtur; Chünki Sen yüzüngni bizdin qachurup yoshurdung, Qebihliklirimizdin bizni solashturghuzdung.
8 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa. Àwa ni amọ̀, ìwọ ni amọ̀kòkò; gbogbo wa jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Biraq hazir, i Perwerdigar, Sen bizning Atimizdursen; Biz séghiz lay, Sen bizning sapalchimizdursen; Hemmimiz bolsaq qolungda yasalghandurmiz;
9 Má ṣe bínú kọjá ààlà, ìwọ Olúwa, má ṣe rántí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa títí láé. Jọ̀wọ́, bojú wò wá, ni a gbàdúrà, nítorí ènìyàn rẹ ni gbogbo wa.
I Perwerdigar, bizge qaratqan ghezipingni zor qilmighaysen, Qebihlikni menggügiche eslep yürmigin; Mana, qarighin, hemmimiz Séning xelqingdurmiz!
10 Àwọn ìlú mímọ́ rẹ ti di aṣálẹ̀; Sioni pàápàá di aṣálẹ̀, Jerusalẹmu di ahoro.
Muqeddes sheherliring janggal, Zionmu janggal bolup qaldi; Yérusalém weyran boldi;
11 Tẹmpili mímọ́ ológo wa, níbi tí àwọn baba wa ti yìn ọ́, ni a ti fi iná sun, àti ohun gbogbo tí í ṣe ìṣúra wa ti dahoro.
Ata-bowimiz Séni medhiyiligen jay, Pak-muqeddeslik, güzel-parlaqliq turalghusi bolghan öyimiz bolsa ot bilen köyüp kül boldi; Qedir-qimmetlik nersilirimizning hemmisi weyran qiliwétildi.
12 Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí, Olúwa, ìwọ ó ha sì tún fi ara rẹ pamọ́ bí? Ìwọ ó ha dákẹ́ kí o sì fìyà jẹ wá kọjá ààlà bí?
Mushu ishlar aldida Özüngni chetke alamsen, i Perwerdigar? Süküt qilip turamsen? Bizni bolushiche xar qilip uriwéremsen?»

< Isaiah 64 >