< Isaiah 64 >

1 Ìwọ ìbá fa ọ̀run ya kí o sì sọ̀kalẹ̀ wá, tí àwọn òkè ńlá yóò fi wárìrì níwájú rẹ!
Hmai neh thingpaem a hlae tih hmai loh tui a tlawk sak bangla na rhal rhoek taengah na ming ming sak ham ni,
2 Gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí iná mú ẹ̀ka igi jó tí ó sì mú kí omi ó hó, sọ̀kalẹ̀ wá kí orúkọ rẹ le di mí mọ̀ fún àwọn ọ̀tá rẹ kí o sì jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè kí ó wárìrì níwájú rẹ!
na mikhmuh ah namtom rhoek khaw tlai uh ni.
3 Nítorí nígbà tí o bá ṣe àwọn ohun ẹ̀rù tí àwa kò nírètí, o sọ̀kalẹ̀ wá, àwọn òkè ńlá sì wárìrì níwájú rẹ̀.
Ka lamtawn pawt te a rhih om la na saii vaengah tlang rhoek na mikhmuh ah na suntlak sak tih moelh uh.
4 Láti ìgbà àtijọ́ kò sí ẹni tí ó gbọ́ rí kò sí etí kan tí ó gbọ́ ọ, kò sí ojú tí ó tí ì rí Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn rẹ, tí ó máa ń ṣe nǹkan lórúkọ àwọn tí ó dúró dè é.
Khosuen lamloh ya uh noek pawt tih, hnakaeng uh pawh. Amah aka rhingda ham a saii namah phoeikah Pathen ti he mik loh ana hmuh moenih.
5 Ìwọ a máa wá fún ìrànlọ́wọ́ àwọn tí wọn ń fi ayọ̀ ṣe ohun tó tọ́, tí ó rántí ọ̀nà rẹ. Ṣùgbọ́n nígbà tí a bẹ̀rẹ̀ sí dẹ́ṣẹ̀ sí wọn, inú bí ọ. Báwo ni a ó ṣe gbà wá là?
Aka ngaingaih tih na longpuei ah duengnah a saii neh nang aka poek rhoek te na doo. Nang khaw na thintoek coeng te. Tedae amih soah kumhal n'tholh dongah n'khang venim.
6 Gbogbo wa ti dàbí ẹnìkan tí ó jẹ́ aláìmọ́, gbogbo òdodo wa sì dàbí èkísà ẹlẹ́gbin; gbogbo wa kákò bí ewé, àti bí afẹ́fẹ́, ẹ̀ṣẹ̀ wa ti gbá wa lọ kúrò.
Kaimih boeih he rhalawt la ka om uh tih kaimih kah duengnah boeih he pumbuk hni bangla om. Kaimih boeih he hawn bangla ka hoo uh tih kaimih thaesainah loh khohli bangla kaimih n'yawn.
7 Ẹnikẹ́ni kò pe orúkọ rẹ tàbí kí ó gbìyànjú láti dì ẹ́ mú; nítorí ìwọ ti fi ojú rẹ pamọ́ fún wa ó sì jẹ́ kí àwa ṣòfò dànù nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Na ming aka khue ham neh nang saicin ham aka haeng khaw om pawh. Kaimih lamloh na maelhmai na thuh tih kaimih kah thaesainah kut ah kaimih nan paci sak.
8 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa. Àwa ni amọ̀, ìwọ ni amọ̀kòkò; gbogbo wa jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Yahovah namah he kaimih napa ni. Kaimih he amlai ni, kaimih aka hlinsai khaw namah ni. Kaimih boeih he na kut kah a bitat ni.
9 Má ṣe bínú kọjá ààlà, ìwọ Olúwa, má ṣe rántí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa títí láé. Jọ̀wọ́, bojú wò wá, ni a gbàdúrà, nítorí ènìyàn rẹ ni gbogbo wa.
BOEIPA na thin bahoeng toek sak aih boeh. Thaesainah khaw a yoeyah la poek boeh. Kaimih na pilnam boeih n'paelki laeh he.
10 Àwọn ìlú mímọ́ rẹ ti di aṣálẹ̀; Sioni pàápàá di aṣálẹ̀, Jerusalẹmu di ahoro.
Namah kah khopuei cim rhoek te khosoek la poeh coeng. Zion khaw khosoek la Jerusalem khopong la poeh.
11 Tẹmpili mímọ́ ológo wa, níbi tí àwọn baba wa ti yìn ọ́, ni a ti fi iná sun, àti ohun gbogbo tí í ṣe ìṣúra wa ti dahoro.
Kaimih kah im cim neh kaimih kah boeimang, a pa rhoek loh nang thangthennah te hmai dongah ungkhang la poeh tih kaimih kah ngailaemnah boeih khaw imrhong la om.
12 Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí, Olúwa, ìwọ ó ha sì tún fi ara rẹ pamọ́ bí? Ìwọ ó ha dákẹ́ kí o sì fìyà jẹ wá kọjá ààlà bí?
Te lalah khaw na thiim uh venim? BOEIPA nim na ngam vetih kaimih mat nan phaep aih veh.

< Isaiah 64 >