< Isaiah 60 >

1 “Dìde, tànmọ́lẹ̀, nítorí ìmọ́lẹ̀ rẹ ti dé, ògo Olúwa sì ràdàbò ọ́.
E ara, kia marama; kua tae mai hoki tou marama, kua whiti te kororia o Ihowa ki a koe.
2 Kíyèsi i, òkùnkùn bo ilẹ̀ ayé òkùnkùn biribiri sì wà lórí àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n Olúwa ràn bò ọ́ ògo rẹ̀ sì farahàn lórí i rẹ.
Tera hoki e hipokina te whenua e te pouri, nga iwi e te pouri kerekere; ka whiti ia a Ihowa ki a koe, ka kitea hoki ki a koe tona kororia.
3 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá sí ìmọ́lẹ̀ rẹ, àti àwọn ọba sí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ rẹ.
A ka haere mai nga tauiwi ki tou marama, nga kingi ki ou hihi, ina whiti mai.
4 “Gbé ojú rẹ sókè, kí o sì wò. Gbogbo wọn ṣa ara jọ pọ̀, wọ́n sì wá sọ́dọ̀ rẹ; àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin yóò wá láti ọ̀nà jíjìn, àwọn ọmọ rẹ obìnrin ni a ó tọ́jú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ.
Kia ara ou kanohi i tetahi taha, i tetahi taha, titiro atu hoki; kei te huihui ratou katoa, e haere mai ana ki a koe; ka haere mai au tama i tawhiti, ka hikitia hoki au tamahine ki nga ringa.
5 Nígbà náà ni ìwọ yóò wò tí ojú rẹ yóò máa dán, ọkàn rẹ yó fò, yó sì kún fún ayọ̀; ọrọ̀ inú Òkun ni a ó kò wá sọ́dọ̀ rẹ, sí ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá.
Ka kite koe i reira, ka whakamaramatia, ka wehi ano tou ngakau, ka nui; no te mea ka tahuri ki a koe nga mea maha o te moana, ka tae ano ki a koe nga taonga o nga tauiwi.
6 Ọ̀wọ́ ìbákasẹ yóò bo gbogbo ilẹ̀ rẹ, àwọn ọ̀dọ́ ìbákasẹ Midiani àti Efani. Àti gbogbo wọn láti Ṣeba yóò wá, wọn yóò mú wúrà àti tùràrí lọ́wọ́ tí wọn yóò sì máa kéde ìyìn Olúwa.
Ka kapi koe i te kamera, he tini, i nga kamera tere o Miriana, o Epa; ka haere mai era katoa i Hepa: me te mau mai ano i te koura, i te whakakakara; ka kauwhautia ano e ratou nga whakamoemiti ki a Ihowa.
7 Gbogbo agbo ẹran ìlú Kedari ni a ó kójọ sọ́dọ̀ rẹ, àwọn àgbò ti Nebaioti yóò sìn ọ́; wọn yóò jẹ́ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà lórí i pẹpẹ mi, bẹ́ẹ̀ ni n ó sì ṣe tẹmpili ògo mi lọ́ṣọ̀ọ́.
Ka huihuia nga hipi katoa o Kerara ki a koe, hei kaimahi mau nga hipi toa o Nepaiota; ka manakohia ratou ina eke ki runga ki taku aata, a ka whakakororiatia e ahau te whare o toku kororia.
8 “Ta ni àwọn wọ̀nyí tí ń fò lọ bí i kurukuru, gẹ́gẹ́ bí àwọn àdàbà sí ìtẹ́ wọn?
Ko wai enei e rere nei ano he kapua, me he kukupa nei, ki o ratou matapihi?
9 Lóòtítọ́ àwọn erékùṣù bojú wò mí; ní ìṣíwájú ni àwọn ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi; mú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ wá láti ọ̀nà jíjìn, pẹ̀lú fàdákà àti wúrà wọn, fún ti ọlá Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli, nítorí òun ti fi ohun dídára ṣe ó lọ́ṣọ̀ọ́.
He pono ka tatari nga motu ki ahau, me nga kaipuke o Tarahihi i te tuatahi, ki te kawe mai i au tama i tawhiti: i a ratou, i ta ratou hiriwa, i ta ratou koura hoki, hei mea ki te ingoa o Ihowa, o tou Atua, ki te Mea Tapu o Iharaira, no te mea ka oti koe te whakakororia e ia.
10 “Àwọn àjèjì yóò tún ògiri rẹ mọ àwọn ọba wọn yóò sì sìn ọ́. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ní ìbínú ni mo lù ọ́, ní àánú èmi yóò ṣe inú rere sí ọ.
Ka hanga ano ou taiepa e nga tangata ke, ko o ratou kingi ano hei kaimahi mau: he riri hoki noku i patu ai ahau i a koe, he manako ia naku i atawhai ai ahau i a koe.
11 Gbogbo ẹnu-bodè rẹ ni yóò wà ní ṣíṣí sílẹ̀, a kì yóò tì wọ́n ní ọ̀sán àti ní òru, tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn ọkùnrin yóò le è kó ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè wá tí àwọn ọba wọn yóò ṣáájú ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ ìṣẹ́gun.
Ka tuwhera tonu ano ou kuwaha: e kore e tutakina i te ao, i te po, kia kawea mai ai nga taonga o nga tauiwi ki a koe, kia arahina mai ai hoki o ratou kingi me ratou.
12 Nítorí pé orílẹ̀-èdè tàbí ilẹ̀ ọba tí kì yóò sìn ọ́ ni yóò parun; pátápátá ni yóò sì dahoro.
Ko te iwi hoki, me te kingitanga, e kore e mahi ki a koe, ka ngaro; ina, ka moti rawa aua iwi.
13 “Ògo Lebanoni yóò wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, igi junifa, firi àti sípírẹ́ṣì papọ̀, láti bu ọlá fún ilé ìsìn mi; àti pé èmi yóò sì ṣe ibi ẹsẹ̀ mi lógo.
Ka tae mai te kororia o Repanona ki a koe, te kauri, te rimu, me te ake ngatahi hei whakapaipai, mo te wahi i toku kainga tapu, a ka whakakororiatia e ahau te wahi o oku waewae.
14 Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin àwọn apọ́nilójú rẹ yóò wá foríbalẹ̀ fún ọ; gbogbo àwọn tí ó ti kẹ́gàn rẹ ni wọn yóò tẹríba níwájú rẹ wọn yóò sì pè ọ́ ní ìlú Olúwa, Sioni ti Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Ka haere mai ano, ka piko ki a koe nga tama a ou kaitukino, a ko te hunga katoa i whakahawea ki a koe, ka piko ki nga kapu o ou waewae; a ka kiia koe, Ko te pa o Ihowa, Ko te Hiona o te Mea Tapu o Iharaira.
15 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ti kórìíra rẹ, a sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀, láìsí ẹnìkan tí ó ń gba ọ̀dọ̀ rẹ kọjá, Èmi yóò ṣe ọ́ ní ìṣògo ayérayé àti ayọ̀ àtìrandíran.
He mea whakarere nei koe i mua, he mea i kinongia, kahore hoki tetahi kia haere i waenganui i a koe, na ka meinga koe e ahau hei mea nui e mau tonu ana, he kaonga ngakau ki nga whakatupuranga maha.
16 Ìwọ yóò mu wàrà gbogbo orílẹ̀-èdè a ó sì fun ọ́ ni ọmú àwọn ọba. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa, èmi ni Olùgbàlà rẹ, Olùdáǹdè rẹ, Alágbára ti Jakọbu.
Ka ngotea ano e koe te waiu o nga tauiwi, ka ngotea te u o nga kingi: a ka mohio koe ko ahau, ko Ihowa, tou kaiwhakaora, tou kaihoko, te Mea Nui o Hakaopa.
17 Dípò idẹ, èmi ó mú wúrà wá fún ọ, dípò fàdákà èmi ó mú irin wá. Dípò igi yóò mú idẹ wá fún ọ, àti irin dípò òkúta. Èmi yóò fi àlàáfíà ṣe àwọn ìjòyè rẹ àti òdodo gẹ́gẹ́ bí alákòóso rẹ.
Ko te parahi ka whakaputaia ketia e ahau hei koura, ko te rino ka whakaputaia ketia hei hiriwa, ka puta ke te rakau hei parahi, ka puta ke nga kohatu hei rino; ko ou kaitohutohu ka meinga he rongo e mau ana, ko ou kaiakiaki he tika.
18 A kì yóò gbọ́ nípa rògbòdìyàn ní ilẹ̀ rẹ mọ́, tàbí ìdahoro àti ìparun nínú agbègbè rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò pe ògiri rẹ ní ìgbàlà àti àwọn ẹnu-bodè rẹ ní ìyìn.
E kore e rangona i muri te mahi nanakia ki tou whenua; te whakamoti te wawahi, ki ou rohe; engari ka kiia, ou taiepa, ko te Whakaoranga, ou kuwaha ko te Whakamoemiti.
19 Òòrùn kì yóò sì jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ní ọ̀sán mọ́, tàbí kí ìtànṣán òṣùpá tún ràn sí ọ mọ́, nítorí Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ayérayé, àti Ọlọ́run rẹ yóò jẹ́ ògo rẹ.
E kore te ra e waiho i muri hei whakamarama mou i te awatea; na, ko te marama e tiaho nei, e kore tera e whakamarama i a koe; ko Ihowa hoki hei whakamarama mou ake ake, ko tou Atua hoki hei whakakororia i a koe.
20 Òòrùn rẹ kì yóò sì wọ̀ mọ́, àti òṣùpá rẹ kì yóò sì wọ òòkùn mọ́; Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ayérayé rẹ, àti àwọn ọjọ́ arò rẹ yóò sì dópin.
Heoi ano hekenga o tou ra, e kore ano tou marama e pewa; no te mea ko Ihowa hei whakamarama pumau mou, a ka mutu nga ra o tou tangihanga.
21 Lẹ́yìn náà ni gbogbo àwọn ènìyàn rẹ yóò di òdodo àwọn ni yóò sì jogún ilẹ̀ náà títí ayé. Àwọn ni irúgbìn tí mo ti gbìn, iṣẹ́ ọwọ́ mi, láti fi ọláńlá mi hàn.
Ko tou iwi hoki, tika katoa, ka pumau tonu ki a ratou te whenua; he peka whakato naku, he mahi na oku ringa, kia whai kororia ai ahau.
22 Èyí tí ó kéré jù nínú yín yóò di ẹgbẹ̀rún kan, èyí tí ó kéré yóò di orílẹ̀-èdè ńlá. Èmi ni Olúwa; ní àkókò rẹ̀, Èmi yóò ṣe èyí kánkán.”
To te mea nohinohi putanga ake, he mano, to te mea iti, he iwi kaha: maku, ma Ihowa, e whakahohoro i tona wa e rite ai.

< Isaiah 60 >