< Isaiah 60 >
1 “Dìde, tànmọ́lẹ̀, nítorí ìmọ́lẹ̀ rẹ ti dé, ògo Olúwa sì ràdàbò ọ́.
E KU iluna, i malamalama, No ka mea, ua hiki mai kou malamalama, A ua puka mai no ka nani o Iehova maluna ou.
2 Kíyèsi i, òkùnkùn bo ilẹ̀ ayé òkùnkùn biribiri sì wà lórí àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n Olúwa ràn bò ọ́ ògo rẹ̀ sì farahàn lórí i rẹ.
No ka mea, aia hoi, e uhi mai no ka poeleele i ka honua, A o ka pouli loa hoi i na kanaka; Aka, e puka mai no o Iehova maluna ou, A ikeia hoi kona nani maluna ou.
3 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá sí ìmọ́lẹ̀ rẹ, àti àwọn ọba sí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ rẹ.
A e hele mai no ko na aina e i kou malamalama, A o na'lii hoi i ka alohilohi o kou puka ana iluna.
4 “Gbé ojú rẹ sókè, kí o sì wò. Gbogbo wọn ṣa ara jọ pọ̀, wọ́n sì wá sọ́dọ̀ rẹ; àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin yóò wá láti ọ̀nà jíjìn, àwọn ọmọ rẹ obìnrin ni a ó tọ́jú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ.
E alawa ae i kou mau maka iluna, e nana mai o a o; Ua akoakoa mai nei lakou a pau, ua hele mai iou la: E hele mai no kau mau keikikane mai kahi loihi mai, A e halihaliia kau mau kaikamahine ma ka aoao.
5 Nígbà náà ni ìwọ yóò wò tí ojú rẹ yóò máa dán, ọkàn rẹ yó fò, yó sì kún fún ayọ̀; ọrọ̀ inú Òkun ni a ó kò wá sọ́dọ̀ rẹ, sí ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá.
Alaila, e ike aku oe, a e olioli hoi, A e lelele kou houpo i ka olioli, a e hoakeaia kou naau, I ka wa e hoohuliia mai iou la ka waiwai o ka moana, A hele mai hoi ia oe na mea ikaika o na aina e.
6 Ọ̀wọ́ ìbákasẹ yóò bo gbogbo ilẹ̀ rẹ, àwọn ọ̀dọ́ ìbákasẹ Midiani àti Efani. Àti gbogbo wọn láti Ṣeba yóò wá, wọn yóò mú wúrà àti tùràrí lọ́wọ́ tí wọn yóò sì máa kéde ìyìn Olúwa.
E uhi mai no ka lehulehu o na kamelo ia oe, O na kamelo mama hoi o Midiana, a me Epa, E hele mai no hoi na mea a pau o Seba; E lawe mai no lakou i ke gula a me ka libano, A e hoikeike lakou i na mea nani o Iehova.
7 Gbogbo agbo ẹran ìlú Kedari ni a ó kójọ sọ́dọ̀ rẹ, àwọn àgbò ti Nebaioti yóò sìn ọ́; wọn yóò jẹ́ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà lórí i pẹpẹ mi, bẹ́ẹ̀ ni n ó sì ṣe tẹmpili ògo mi lọ́ṣọ̀ọ́.
E hoakoakoaia mai iou la na holoholona a pau o Kedara, E lawelawe na hipakane o Nebaiota nau; E pii mai no lakou maluna o ko'u kuahu me ka oluoluia'ku, A e hoonani no au i ko'u hale nani.
8 “Ta ni àwọn wọ̀nyí tí ń fò lọ bí i kurukuru, gẹ́gẹ́ bí àwọn àdàbà sí ìtẹ́ wọn?
Owai keia poe e lele nei, me he ao la, E like hoi me na manu nunu i ko lakou mau pukahale?
9 Lóòtítọ́ àwọn erékùṣù bojú wò mí; ní ìṣíwájú ni àwọn ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi; mú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ wá láti ọ̀nà jíjìn, pẹ̀lú fàdákà àti wúrà wọn, fún ti ọlá Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli, nítorí òun ti fi ohun dídára ṣe ó lọ́ṣọ̀ọ́.
He oiaio no, e kakali ko na aina ia'u, A o na moku o Taresisa na mea mua, E lawe mai i kau mau keikikane, mai kahi mamao aku, I ko lakou kala, a me ko lakou gula pu me lakou, No ka inoa o Iehova, o kou Akua, A no ka Mea Hemolele o ka Iseraela, No ka mea, ua hoonani mai oia ia oe.
10 “Àwọn àjèjì yóò tún ògiri rẹ mọ àwọn ọba wọn yóò sì sìn ọ́. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ní ìbínú ni mo lù ọ́, ní àánú èmi yóò ṣe inú rere sí ọ.
Na na keiki a ka malihini e hana i kou mau pa, A na ko lakou alii e lawelawe nau; No ka mea, i ko'u ukiuki, hahau aku no au ia oe, Aka, i ko'u lokomaikai, ua aloha aku au ia oe.
11 Gbogbo ẹnu-bodè rẹ ni yóò wà ní ṣíṣí sílẹ̀, a kì yóò tì wọ́n ní ọ̀sán àti ní òru, tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn ọkùnrin yóò le è kó ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè wá tí àwọn ọba wọn yóò ṣáájú ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ ìṣẹ́gun.
Nolaila, e hamama mau no kou mau pukapa, Aole lakou e paniia i ke ao, aole i ka po, I lawe mai ai na kanaka iou la i ka waiwai o ko na aina e, I alakaiia mai ai hoi ko lakou poe alii.
12 Nítorí pé orílẹ̀-èdè tàbí ilẹ̀ ọba tí kì yóò sìn ọ́ ni yóò parun; pátápátá ni yóò sì dahoro.
No ka mea, o ka lahuikanaka, a me ke aupuni hookauwa ole nau, e make ia; Oia, e anai loa ia kela mau lahuikanaka.
13 “Ògo Lebanoni yóò wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, igi junifa, firi àti sípírẹ́ṣì papọ̀, láti bu ọlá fún ilé ìsìn mi; àti pé èmi yóò sì ṣe ibi ẹsẹ̀ mi lógo.
E hele mai no iou la ka nani o Lebanona, O ka laau kaa, o ka tidara, a me ka tiasura pu, E hoonani ai i kahi o ko'u keenakapu, A e hoohanohano wau i kahi o kou mau wawae.
14 Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin àwọn apọ́nilójú rẹ yóò wá foríbalẹ̀ fún ọ; gbogbo àwọn tí ó ti kẹ́gàn rẹ ni wọn yóò tẹríba níwájú rẹ wọn yóò sì pè ọ́ ní ìlú Olúwa, Sioni ti Ẹni Mímọ́ Israẹli.
O na keiki hoi a ka poe i hookaumaha ia oe, E hele kulou mai no lakou imua ou; A o ka poe a pau i hoowahawaha ia oe, E kulou no lakou ma na kapuwai o kou mau wawae; A e kapa aku no lakou ia oe, O ke kulanakauhale o Iehova, O ka Ziona hoi o ka Mea Hemolele o ka Iseraela.
15 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ti kórìíra rẹ, a sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀, láìsí ẹnìkan tí ó ń gba ọ̀dọ̀ rẹ kọjá, Èmi yóò ṣe ọ́ ní ìṣògo ayérayé àti ayọ̀ àtìrandíran.
No kou haaleleia, a no kou huhuia, I hele ole ai ke kanaka mawaena ou, E hoolilo no wau ia oe i mea hanohano mau loa, He mea olioli hoi, ia hanauna aku, ia hanauna aku.
16 Ìwọ yóò mu wàrà gbogbo orílẹ̀-èdè a ó sì fun ọ́ ni ọmú àwọn ọba. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa, èmi ni Olùgbàlà rẹ, Olùdáǹdè rẹ, Alágbára ti Jakọbu.
E omo no oe i ka waiu o ko na aina e, Ma ka u o na'lii kau e omo ai, A e ike auanei oe, owau, o Iehova kou Ola, A o kou Hoolapanai, oia ka Mea Mana o ka Iakoba.
17 Dípò idẹ, èmi ó mú wúrà wá fún ọ, dípò fàdákà èmi ó mú irin wá. Dípò igi yóò mú idẹ wá fún ọ, àti irin dípò òkúta. Èmi yóò fi àlàáfíà ṣe àwọn ìjòyè rẹ àti òdodo gẹ́gẹ́ bí alákòóso rẹ.
No ke keleawe, e lawe mai au i ke gula, A no ka hao, e lawe mai au i ke kala, A no ka laau, he keleawe, a no na pohaku, he hao; E hoolilo no hoi au i kou poe kiai, i poo hoomalu, A me kou poe luna, i poe hoopono.
18 A kì yóò gbọ́ nípa rògbòdìyàn ní ilẹ̀ rẹ mọ́, tàbí ìdahoro àti ìparun nínú agbègbè rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò pe ògiri rẹ ní ìgbàlà àti àwọn ẹnu-bodè rẹ ní ìyìn.
Aole e lohe hou ia ka hao wale ana ma kou aina, Aole hoi ka hookaumaha, a me ka anai ana, ma kou mau mokuna; Aka, e kapa iho no oe i kou mau pa, He ola, A me kou mau pukapa hoi, He hoonani.
19 Òòrùn kì yóò sì jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ní ọ̀sán mọ́, tàbí kí ìtànṣán òṣùpá tún ràn sí ọ mọ́, nítorí Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ayérayé, àti Ọlọ́run rẹ yóò jẹ́ ògo rẹ.
O ka la, aole ia o kou malamalama hou aku ma ke ao, Aole hoi e hoomalamalama mai ka mahina ia oe, no ka alohilohi; Aka, o Iehova auanei kou malamalama mau loa, A o kou Akua hoi kou hanohano.
20 Òòrùn rẹ kì yóò sì wọ̀ mọ́, àti òṣùpá rẹ kì yóò sì wọ òòkùn mọ́; Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ayérayé rẹ, àti àwọn ọjọ́ arò rẹ yóò sì dópin.
Aole e napoo hou kou la, Aole hoi e laweia'ku kou mahina: No ka mea, o Iehova auanei kou malamalama mau loa, A e pau auanei na la o kou kumakena ana.
21 Lẹ́yìn náà ni gbogbo àwọn ènìyàn rẹ yóò di òdodo àwọn ni yóò sì jogún ilẹ̀ náà títí ayé. Àwọn ni irúgbìn tí mo ti gbìn, iṣẹ́ ọwọ́ mi, láti fi ọláńlá mi hàn.
A e lilo auanei kou poe kanaka, i poe pono; A e noho mau loa no hoi lakou ma ka aina, O ka lala a'u i kanu ai, o ka hana hoi a kuu mau lima, I hoomaikaiia mai ai au.
22 Èyí tí ó kéré jù nínú yín yóò di ẹgbẹ̀rún kan, èyí tí ó kéré yóò di orílẹ̀-èdè ńlá. Èmi ni Olúwa; ní àkókò rẹ̀, Èmi yóò ṣe èyí kánkán.”
E lilo auanei ka mea uuku i hookahi tausani, A o ka mea liilii i lahuikanaka ikaika: Owau, o Iehova, e hoowikiwiki no au ia i kona manawa.