< Isaiah 57 >
1 Olódodo ṣègbé kò sí ẹnìkan tí ó rò ó lọ́kàn ara rẹ̀; a mú àwọn ẹni mímọ́ lọ, kò sì ṣí ẹni tó yé pé a ti mú àwọn olódodo lọ láti yọ wọ́n kúrò nínú ibi.
Moloidafa dunu da bogosa, be eno dunu da dawa: hame laha, amola ilia da hame asigisa. Be moloi dunu da bogosea, bidi hamosu da ilima se hame iaha.
2 Gbogbo àwọn tí ń rìn déédé ń wọ inú àlàáfíà; wọ́n rí ìsinmi bí wọ́n ti ń sùn nínú ikú.
Nowa da noga: iwane esalea da bogosea, olofosu amola helefisu ba: mu.
3 “Ṣùgbọ́n ẹ súnmọ́ ìhìn-ín, ẹ̀yin ọmọ aláfọ̀ṣẹ, ẹ̀yin irú-ọmọ panṣágà àti àgbèrè!
“Dilia wadela: i hamosu dunu! Guiguda: fofada: musa: misa! Dilia hou da wamuni dawa: su dunu, amola inia uda adole lasu dunu, amola hina: da: i bidi lasu uda, ilia hou defele wadela: idafa.
4 Ta ni ó fi ń ṣẹlẹ́yà? Ta ni o ń yọ ṣùtì sí tí o sì yọ ahọ́n síta? Ẹ̀yin kì í ha ṣe ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn bí, àti ìran àwọn òpùrọ́?
Dilia da nowama oufesega: sala: ? Dilia ogogosu dunu! Nowama oufesega: sala: ?
5 Ẹ gbinájẹ fún ìṣekúṣe láàrín igi óákù àti lábẹ́ gbogbo igi tí ń gbilẹ̀; ẹ fi àwọn ọmọ yín rú ẹbọ nínú kòtò jíjìn àti lábẹ́ àwọn pàlàpálá òkúta.
Dilia da ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadomusa: , sema gosa: su ifa haguduga wadela: i udigili uda lasu hou hamonana. Dilia da magufu gelabo hano gadenene diala, amo ganodini dilia mano gobele salimusa: medole legesa.
6 Àwọn ère tí ó wà ní àárín òkúta dídán wọ́n n nì, nínú kòtò jíjìn ni ìpín in yín; àwọ̀n ni ìpín in yín. Bẹ́ẹ̀ ni, sí wọn ni ẹ ti ta ọrẹ ohun mímu yín sílẹ̀ àti láti ta ọrẹ ìyẹ̀fun. Nítorí àwọn nǹkan wọ̀nyí, ǹjẹ́ ó yẹ kí n dáwọ́ dúró?
Dilia da enemei igi amo hanoga lasea, amoma ‘gode’ dio asuli, nodone sia: ne gadosa. Dilia da ilima gobele salimusa: , waini hano sogadigisa amola ilima ima: ne gagoma gaguli maha. Dilia adi dawa: bela: ? Na da amo hou hahawane ba: sala: ? Hame mabu!
7 Ìwọ ti ṣe ibùsùn rẹ lórí òkè gíga tí ó rẹwà; níbẹ̀ ni ẹ lọ láti lọ ṣe ìrúbọ yín.
Dilia da ogogosu ‘gode’ ilima gobele salasu hamoma: ne amola wadela: i ledo uda lasu hou hamoma: ne, goumi sedade amoba: le heda: sa.
8 Lẹ́yìn àwọn ìlẹ̀kùn yín àti òpó ìlẹ̀kùn yín níbẹ̀ ni ẹ fi àwọn àmì òrìṣà yín sí. Ní kíkọ̀ mí sílẹ̀, ẹ ṣí ibùsùn yín sílẹ̀, ẹ gun orí rẹ̀ lọ, ẹ sì ṣí i sílẹ̀ gbagada; ẹ ṣe àdéhùn pẹ̀lú àwọn tí ẹ fẹ́ràn ibùsùn wọn, ẹ̀yin sì ń wo ìhòhò wọn.
Dilia da ledo bagade loboga hamoi ‘gode’ amo dilia logo ga: su amo ganodini legesa. Dilia da Na fisisa. Dilia da abula gisa: le, dilia amola wadela: i hina: da: i bidi lasu uda gilisili da: i nabadowane diaheda: su bagade amoga fila heda: sa. Amola amogawi dilia da dilia wadela: i uda hanai hou gumisa.
9 Ẹ̀yin lọ sí Moleki pẹ̀lú òróró olifi ẹ sì fi kún òórùn dídùn yín. Ẹ rán ikọ̀ yín lọ jìnnà réré; ẹ sọ̀kalẹ̀ sí ibojì pẹ̀lú! (Sheol )
Dilia da gabusiga: manoma legelalu, ogogosu ‘gode’ amo Moulege amoma nodone sia: ne gadomusa: ahoa. Dilia da ‘gode’ liligi eno ilima sia: ne gadomusa: amo hogoma: ne, dilia da sia: ne iasu dunu soge sedagaga asuna ahoa. Amola amo hogomusa: dilia da osobo bagade baligili, bogosu sogebi amoga ahoa. (Sheol )
10 Àwọn ọ̀nà yín gbogbo ti mú àárẹ̀ ba á yín, ṣùgbọ́n ẹ kò ní sọ pé, ‘Kò sí ìrètí mọ́?’ Ẹ rí okun kún agbára yín, nípa bẹ́ẹ̀ òòyì kò kọ́ ọ yín.
Dilia da eno ‘gode’ hogomusa: , hele bagade naba. Be amo hogosu hou dilia fisimusa: hame dawa: Dilia ledo bagade loboga hamoi ‘gode’ da dilima gasa iaha amo dawa: beba: le, dilia gasa da bu gaheabolo laha.”
11 “Ta ni ó ń pá yín láyà tí ń bà yín lẹ́rù tí ẹ fi ń ṣèké sí mi, àti tí ẹ̀yin kò fi rántí mi tàbí kí ẹ rò yí nínú ọkàn yín? Ǹjẹ́ kì í ṣe nítorí dídákẹ́ jẹ́ẹ́ mi fún ìgbà pípẹ́ tí ẹ̀yin kò fi bẹ̀rù mi?
Hina Gode da amane sia: sa, “Amo ‘gode’ ilia da nowala: ? Dilia da ilima beda: iba: le, Nama ogogosa, amola dilia da Na gogoleidafa. Na da eso bagohame ouiya: le, esalebeba: le, dilia da Nama nodosu hou yolesila: ?
12 Èmi yóò ṣí òdodo yín páyà àti iṣẹ́ yín, wọn kì yóò sì ṣe yín ní àǹfààní.
Dilia hou da moloidafa dilisu dawa: lala. Be Na da dunu huluane ba: ma: ne, dilia wadela: i hou olelemu. Amola dilia loboga hamoi ‘gode’ da dili fidimu gogolemu.
13 Nígbà tí ẹ bá kígbe fún ìrànlọ́wọ́ ẹ jẹ́ kí àkójọ àwọn ère yín gbà yín! Atẹ́gùn yóò gbá gbogbo wọn lọ, èémí lásán làsàn ni yóò gbá wọn lọ. Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá fi mí ṣe ààbò rẹ̀ ni yóò jogún ilẹ̀ náà yóò sì jogún òkè mímọ́ mi.”
Dilia fidima: ne wele sia: ne disia, dilia loboga hamoi ‘gode’ liligi dili fidimu da defea. Fo fonobahadi da amo liligi mini masa: ne dawa: Be nowa da Na dafawaneyale dawa: beba: le da Isala: ili sogega esalumu amola Na Debolo diasu ganodini Nama nodone sia: ne gadomu.”
14 A ó sì sọ wí pé: “Tún mọ, tún mọ, tún ọ̀nà náà ṣe! Ẹ mú àwọn ohun ìkọ̀sẹ̀ kúrò ní ọ̀nà àwọn ènìyàn mi.”
Hina Gode da amane sia: sa, “Na fi dunu Nama bu sinidigima: ne, ilia logo fodole, momagema! Logo ga: su liligi huluane fadegama.
15 Nítorí èyí ni ohun tí Ẹni gíga àti ọlọ́lá jùlọ wí ẹni tí ó wà títí láé, tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ mímọ́: “Mo ń gbé ní ibi gíga àti ibi mímọ́, ṣùgbọ́n pẹ̀lú ẹni n nì tí ó ní ìròbìnújẹ́ àti ẹ̀mí ìrẹ̀lẹ̀, láti sọ ẹ̀mí onírẹ̀lẹ̀ náà jí àti láti sọ ẹ̀mí oníròbìnújẹ́ n nì jí.
Na da gaguia gadoi amola Hadigi Gode, eso huluane Fifi Ahoanusu Gode esala. Na da gadodafa amola hadigi sogebi amo ganodini esala. Be Na da asaboi dunu ilia wadela: i hou fofada: nanu Nama sinidigisa, agoaiwane dunu ilima Na da gilisili esala. Bai Na da ilima hame beda: su hou, amola hobea misunu hou da noga: idafa amo dafawane esaloma: beyale dawa: su hou, ilima bu iaha.
16 Èmi kì yóò fẹ̀sùn kan ni títí láé, tàbí kí n máa bínú sá á, nítorí nígbà náà ni ọkàn ènìyàn yóò rẹ̀wẹ̀sì níwájú mi èémí ènìyàn tí mo ti dá.
Na da Na fi dunu ilima esalusu i dagoi, amola ilia da da: i dioiba: le dafasa: besa: le, Na da eso huluane ilima diwaneya hame udidimu, amola eso huluane ilima hame ougimu.
17 Inú bí mi nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀kánjúwà rẹ̀; mo fìyà jẹ ẹ́, mo sì fojú mi pamọ́ ní ìbínú; síbẹ̀, ó tẹ̀síwájú nínú tinú-mi-ni n ó ṣe ọ̀nà rẹ̀.
Ilia da wadela: i hou amola uasu hou hamobeba: le, Na da ilima ougi galu. Amaiba: le, Na da ilima se iasu amola ili yolesiagai. Be ilia da amo sisasu mae dawa: le, hi hanaiga udigili asi.
18 Èmi ti rí ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, ṣùgbọ́n Èmi yóò wò ó sàn; Èmi yóò tọ́ ọ ṣọ́nà n ó sì mú ìtùnú tọ̀ ọ́ wá,
Na da ilia hou ba: i dagoi, be Na da ili uhinisimu. Na da ili bisili masunu, amola ili fidimu, amola nowa da da: i dioiba: le, dinana, amo Na da ilia dogo denesinisimu.
19 ní dídá ìyìn sí ètè àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ní Israẹli. Àlàáfíà, àlàáfíà fún àwọn tí ó wà lókèèrè àti nítòsí,” ni Olúwa wí, “Àti pé, Èmi yóò wo wọ́n sàn.”
Na da gadenene dunu fi esala, amola fi eno sedaga esala ilima olofosu ima: ne sia: mu. Na da Na fi dunu uhinisimu.
20 Ṣùgbọ́n àwọn ìkà dàbí i ríru Òkun tí kò le è sinmi, tí ìgbì rẹ̀ ń rú pẹ̀tẹ̀pẹ́tẹ̀ àti ẹrọ̀fọ̀ sókè.
Be wadela: i hamosu dunu da hano wayabo bagade, ea gafului agoane yagugusa. Ilia helefisu hame dawa: , amola gafului da fafu amola ledo bibiagosa.
21 “Kò sí àlàáfíà fún àwọn ìkà,” ni Ọlọ́run mi wí.
Be wadela: i hamosu dunu da olofosu hamedafa ba: mu,” Hina Gode da amane sia: sa.