< Isaiah 56 >
1 Èyí ni ohun ti Olúwa sọ: “Ẹ pa ìdájọ́ mọ́ ẹ sì ṣe ohun tí ó tọ̀nà, nítorí ìgbàlà mi súnmọ́ tòsí àti òdodo mi ni a ó fihàn láìpẹ́ jọjọ.
He ni BOEIPA loh a thui. Tiktamnah he ngaithuen lamtah duengnah te saii lah. Kai kah khangnah ha pawk ham neh ka duengnah a phoe hamla yoei coeng.
2 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó ṣe èyí, àti fún ọmọ ènìyàn tí ó dìímú ṣinṣin, tí ó pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ láì bà á jẹ́, tí ó sì pa ọwọ́ rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ibi ṣíṣe.”
Yoethen hlanghing long tah hekah he a saii tih hlang capa long khaw te te a pom. Sabbath aka tuem loh te te poeih vetih a kut aka ngaithuen loh boethae pakhat khaw saii ve ne.
3 Má ṣe jẹ́ kí àjèjì kan tí ó ti di ara rẹ̀ mọ́ Olúwa sọ wí pé, “Olúwa yóò yà mí sọ́tọ̀ kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.” Àti kí ìwẹ̀fà kan ṣe àròyé pé, “Igi gbígbẹ lásán ni mí.”
BOEIPA taengah aka naep kholong ca loh, “BOEIPA loh kai tah a pilnam taeng lamloh m'boe khaw m'boe mai ni,” a ti ham khaw thui boel saeh. Imkhoem long khaw, “Kai tah thing koh ni he,” ti boel saeh.
4 Nítorí pé báyìí ni Olúwa wí: “Sí àwọn ìwẹ̀fà yìí tí ó pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́, tí wọ́n yan ohun tí ó dùn mọ́ mi tí wọ́n sì di májẹ̀mú mi mú ṣinṣin
BOEIPA loh imkhoem taengah khaw he ni a. thui. Kai kah Sabbath aka tuem rhoek neh kai ngaih la aka tuek rhoek long tah kai kah paipi te a pom uh.
5 fún wọn ni Èmi yóò fún nínú tẹmpili àti àgbàlá rẹ̀ ìrántí kan àti orúkọ kan tí ó sàn ju àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin àti ọ̀dọ́mọbìnrin, Èmi yóò fún wọn ní orúkọ ayérayé tí a kì yóò ké kúrò.
Kai im khui neh ka vongtung khuikah ka kut te amih taengla ka paek ni. Ming then te capa rhoek lakah khaw canu rhoek kah lakah khaw kumhal ming la anih taengah ka paek vetih phae voel mahpawh.
6 Àti àwọn àjèjì tí ó so ara wọn mọ́ Olúwa láti sìn ín, láti fẹ́ orúkọ Olúwa àti láti foríbalẹ̀ fún un gbogbo àwọn tí ń pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ láì bà á jẹ́ àti tí wọ́n sì di májẹ̀mú mi mú ṣinṣin—
BOEIPA taengah aka naep kholong ca rhoek tah amah aka bong la, BOEIPA ming aka lungnah ham neh amah taengah sal la, Sabbath aka poeih lamloh aka ngaithuen boeih neh ka paipi aka pom rhoek taengah tah,
7 àwọn wọ̀nyí ni èmi yóò mú wá òkè mímọ́ mi, èmi ó sì fún wọn ní ayọ̀ nínú ilé àdúrà mi. Ẹbọ sísun wọn àti ìrúbọ wọn, ni a ó tẹ́wọ́gbà lórí i pẹpẹ mi; nítorí a ó máa pe ilé mi ní ilé àdúrà fún gbogbo orílẹ̀-èdè.”
kamah kah hmuencim tlang la ka khuen vetih amih te ka thangthuinah im ah ko ka hoe sak ni. Amih kah hmueihhlutnah neh hmueih te ka hmueihtuk dongkah kolonah la om ni. Ka im te pilnam tom kah thangthuinah im la a khue ni.
8 Olúwa Olódùmarè sọ wí pé— ẹni tí ó kó àwọn àtìpó Israẹli jọ: “Èmi yóò kó àwọn mìíràn jọ pẹ̀lú wọn yàtọ̀ sí àwọn tí a ti kójọ.”
A heh tangtae Israel aka coi ka Boeipa Yahovah kah olphong dongah tah anih ka coi phoeiah anih taengla ka coi pueng ni.
9 Ẹ wá, gbogbo ẹ̀yin ẹranko inú pápá, ẹ wá jẹ àwọn ẹranko inú igbó run!
Khohmuen a mulhing boeih neh duup khuikah mulhing boeih caak hamla lo laeh oe.
10 Àwọn olùṣọ́ Israẹli fọ́jú, gbogbo wọn ṣe aláìní ìmọ̀; gbogbo wọn jẹ́ adití ajá, wọn kò lè gbó; wọ́n sùn sílẹ̀ wọ́n ń lálàá, wọ́n fẹ́ràn láti máa sùn.
Anih aka tawt la aka tawt rhoek khaw amamih boeih a mikdael uh coeng tih amamih khaw boeih ming uh thae pawh. Ui olmueh rhoek loh a naak ham coeng pawh. Ihnga uh, yalh uh, mikku te a lungnah uh.
11 Wọ́n jẹ́ àwọn ajá tí ó kúndùn púpọ̀; wọn kì í ní ànító. Wọ́n jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn tí kò ní òye; olúkúlùkù ń yà ṣọ́nà ara rẹ̀, ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn sì wá ère tirẹ̀.
Hinglu ui tlung rhoek te a cungnah a ming uh moenih. Amih aka dawn loh a pum la thuicaih ham ming uh pawh. A bawtnah ah hlang loh a longpuei te a mueluemnah la a hooi uh.
12 Igbe ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn ni wí pé, “Wá, fún mi ní ọtí wáìnì! Jẹ́ kí a mu ọtí líle wa lámu yó ọ̀la yóò sì dàbí òní, tàbí kí ó dára jù bẹ́ẹ̀ lọ.”
Lo laeh misur than sih lamtah yu khaw mii sih. Tahae khohnin kah bangla thangvuen ah a then la muep om khungdaeng bitni.