< Isaiah 55 >

1 “Ẹ wá, gbogbo ẹ̀yin tí òǹgbẹ ń gbẹ, ẹ wá sí ibi omi; àti ẹ̀yin tí kò ní owó; ẹ wá, ẹ rà kí ẹ sì jẹ! Ẹ wá ra wáìnì àti wàrà láìsí owó àti láìdíyelé.
LEUM GOD El fahk, “Fahsru, kowos nukewa su malu — Kof pa inge! Fahsru kowos su wangin mani la — Mongo ac nim! Fahsru! Moul wain ac milk — Ac fah wangin molo!
2 Èéṣe tí ẹ fi ń ná owó fún èyí tí kì í ṣe àkàrà àti làálàá yín lórí ohun tí kì í tẹ́nilọ́rùn? Tẹ́tí sílẹ̀, tẹ́tí sí mi, kí ẹ sì jẹ èyí tí ó dára, bẹ́ẹ̀ ni ọkàn yín yóò láyọ̀ nínú ọrọ̀ tí ó bójúmu.
Efu ku kowos sisi mani ke ma ac tia akinsewowoye kowos? Efu ku kowos sisla molin orekma lowos ac srakna masrinsral? Porongeyu ac oru ma nga fahk uh, Na kowos fah engankin mwe mongo ma wo emeet uh.
3 Tẹ́tí sílẹ̀ kí o sì wá sọ́dọ̀ mi; gbọ́ tèmi, kí ọkàn rẹ lè wà láààyè. Èmi yóò dá májẹ̀mú ayérayé pẹ̀lú rẹ, ìfẹ́ òtítọ́ tí mo ṣèlérí fún Dafidi.
“Mwet luk, porongeyu ac fahsru nu yuruk; Fahsru nu yuruk, na ac fah oasr moul lowos! Nga ac oru sie wuleang inmasrlok ac kowos su wangin saflaiya, Ac nga fah sot nu suwos mwe insewowo ma nga tuh wuleang nu sel David.
4 Kíyèsi i, mo ti fi òun ṣe ẹlẹ́rìí fún àwọn ènìyàn, olórí àti apàṣẹ fún àwọn ènìyàn.
Nga oru tuh elan sie mwet kol ac leum lun mutunfacl uh, Ac nga akkalemye ku luk kacl.
5 Lóòtítọ́ ìwọ yóò ké sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò mọ̀ àti orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò mọ̀ ni yóò sáré tọ̀ ọ́ wá, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ Ẹni Mímọ́ Israẹli nítorí pé ó ti fi ohun dídára dá ọ lọ́lá.”
Inge kowos fah suli mutunfacl saya uh. Sie pacl ah, elos tuh tia etekowos, A inge elos ac kasrusr tuku in wi kowos! Nga, LEUM GOD lowos, God mutal lun Israel, Fah oru ma inge nukewa in sikyak; Nga fah sot nu suwos sunak ac wolana.”
6 Ẹ wá Olúwa nígbà tí ẹ lè rí i; ẹ pè é nígbà tí ó wà nítòsí.
Suk LEUM GOD ke kowos srakna ku in konalak, Pre nu sel inge ke El apkuran.
7 Jẹ́ kí ìkà kí ó kọ ọ̀nà rẹ̀ sílẹ̀ àti ènìyàn búburú èrò rẹ̀. Jẹ́ kí ó yípadà sí Olúwa, Òun yóò sì ṣàánú fún un, àti sí Ọlọ́run wa, nítorí Òun yóò sì dáríjì.
Lela mwet koluk in sisla ouiyen moul lalos, Ac in ekulla ouiyen nunak lalos. Lela elos in forla nu sin LEUM GOD lasr; El pakoten ac sa in nunak munas.
8 “Nítorí èrò mi kì í ṣe èrò yín, tàbí ọ̀nà yín a ha máa ṣe ọ̀nà mi,” ni Olúwa wí.
LEUM GOD El fahk, “Nunak luk, tia oana nunak lowos, Ac inkanek luk siena liki inkanek lowos.
9 “Gẹ́gẹ́ bí ọ̀run ti ga ju ayé lọ, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀nà mi ga ju ọ̀nà yín lọ àti èrò mi ju èrò yín lọ.
Oana ke kusrao arulana fulat liki faclu, Ouinge inkanek luk fulat liki inkanek lowos, Ac nunak luk liki nunak lowos.
10 Gẹ́gẹ́ bí òjò àti yìnyín ti wálẹ̀ láti ọ̀run tí kì í sì padà sí ibẹ̀ láì bomirin ilẹ̀ kí ó sì mú kí ó tanná kí ó sì rudi, tó bẹ́ẹ̀ tí yóò fi mú irúgbìn fún afúnrúgbìn àti àkàrà fún ọ̀jẹun,
“Kas luk oana snow ac af Ma kahk inkusrao me in aksroksrokye faclu. Af uh oru sacn uh in kap Tuh in oasr fita mwe yok, ac in isus fahko mwe mongo.
11 bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ mi tí ó jáde láti ẹnu mi wá; kì yóò padà sọ́dọ̀ mi lọ́wọ́ òfo, ṣùgbọ́n yóò ṣe ohun tí mo fẹ́, yóò sì mú ète mi tí mo fi rán an wá sí ìmúṣẹ.
Ac fah oapana inge ke kas ma nga fahk uh — Ac fah tia tafongla liki ma nga sapkin uh, A ac fah orekla ma nukewa fal nu ke lungse luk.
12 Ẹ̀yin yóò jáde lọ ní ayọ̀ a ó sì darí i yín lọ ní àlàáfíà; òkè ńlá ńlá àti kéékèèké yóò bú sí orin níwájú yín àti gbogbo igi inú pápá yóò máa pàtẹ́wọ́.
“Kowos ac fah som liki acn Babylon ke engan lulap; Ac fah kokola kowos liki siti uh in misla. Eol uh ac inging uh fah wowoyak ke on, Ac sak uh fah sasa ke engan.
13 Dípò igi ẹ̀gún ni igi junifa yóò máa dàgbà, àti dípò ẹ̀wọ̀n, maritili ni yóò yọ. Èyí yóò wà fún òkìkí Olúwa, fún àmì ayérayé, tí a kì yóò lè parun.”
Sak cypress fah kap ke acn ma mah fakfuk uh kapak we. Acn ma oasr kokul we inge, sak myrtle fah kapak we. Pa inge sie mwe akul ma ac oanna nwe tok, Sie mwe akesmak ke ma nga, LEUM GOD, orala.”

< Isaiah 55 >