< Isaiah 54 >
1 “Kọrin, ìwọ obìnrin àgàn, ìwọ tí kò tí ì bímọ rí; bú sí orin, ẹ hó fún ayọ̀, ẹ̀yin tí kò tí ì rọbí rí; nítorí pé púpọ̀ ni ọmọ àwọn obìnrin ìsọdahoro ju ti ẹni tí ó ní ọkọ,” ni Olúwa wí.
Jehova Nyasaye owacho niya, “Wer, yaye in dhako ma migumba, in ma ok inywol nyithindo; wer matek, ka igoyo koko gi ilo, in mane muoch ok okayi; nimar dhako ma migumba nobed gi nyithindo, mangʼeny moloyo dhako man-gi dichwo.
2 Fẹ ibi àgọ́ rẹ lójú sí i, fẹ aṣọ àgọ́ rẹ kí ó gbòòrò sí i, má ṣe dá a dúró; sọ okùn rẹ di gígùn, mú òpó rẹ lágbára sí i.
Ket kar hembi obed maduongʼ, yar ragengʼ mar hembi obed malach, kendo kik idog chien; tud tondene obed maboyo bende igur loyene motegno.
3 Nítorí ìwọ ó fẹ̀ sọ́tùn àti sí òsì; ìrandíran rẹ yóò jogún àwọn orílẹ̀-èdè, wọn yóò sì dó sí ahoro àwọn ìlú wọn.
Nimar ibiro medori malach kichomo bat korachwich kendo kidhi bat koracham; ogandani noma ogendini pinjegi mi dagie e mier madongo makoro owe gundini.
4 “Má ṣe bẹ̀rù, ìtìjú kò ní ṣubú lù ọ́. Má ṣe bẹ̀rù ìdójútì, a kì yóò kàn ọ́ lábùkù. Ìwọ yóò gbàgbé ìtìjú ìgbà èwe e rẹ, ìwọ kì yóò sì rántí ẹ̀gàn ìgba-opo rẹ mọ́.
“Kik ibed maluor; nikech ok iniyud wichkuot. Kik ibed gi luoro mar yudo wichkuot; nikech ok nojari. Wiyi nowil gi wichkuot mane iyudo ka in nyako, kendo ok inichak ipar chandruok mane ineno kane ibedo dhako ma chwore otho.
5 Nítorí Ẹlẹ́dàá rẹ ni ọkọ rẹ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀ Ẹni Mímọ́ Israẹli ni Olùràpadà rẹ; a sì ń pè é ní Ọlọ́run gbogbo ayé.
Nimar Jachwechni e chwori, Jehova Nyasaye Maratego e nyinge midendego, Jal Maler mar Israel e Jaresni; iluonge ni Nyasach piny ngima.
6 Olúwa yóò pè ọ́ padà àfi bí ẹni pé obìnrin tí a kọ̀sílẹ̀ tí a sì bà lọ́kàn jẹ́ obìnrin tí a fẹ́ ní ọ̀dọ́, tí a sì wá jákulẹ̀,” ni Olúwa wí.
Jehova Nyasaye nodwogi ire, mana ka dhako manoyudo osejwangʼ, kendo ma chunye nigi lit ahinya, en dhako mane okend ka nyako ngili kae to bangʼe ojwangʼ,” Nyasachi ema owacho mano.
7 “Fún ìgbà díẹ̀ ni mo kọ̀ ọ́ sílẹ̀, ṣùgbọ́n pẹ̀lú ọkàn ìyọ́nú èmi yóò mú ọ padà wá.
“Kuom kinde manok asejwangʼi, to koro abiro duogi ira gi kech mangʼeny.
8 Ní ríru ìbínú. Mo fi ojú pamọ́ fún ọ fún ìṣẹ́jú kan, ṣùgbọ́n pẹ̀lú àánú àìnípẹ̀kun Èmi yóò síjú àánú wò ọ́,” ni Olúwa Olùdáǹdè rẹ wí.
E kinde mane an gi mirima mangʼeny ne apandoni wangʼa kuom ndalo manok, to koro gi ngʼwono mochwere an-gi kech kuomi,” Jehova Nyasaye ma Jaresni ema owacho.
9 “Sí mi, èyí dàbí i àwọn ọjọ́ Noa, nígbà tí mo búra pé àwọn omi Noa kì yóò tún bo ilẹ̀ ayé mọ́. Bẹ́ẹ̀ ni nísinsin yìí mo ti búra láti má ṣe bínú sí ọ, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò bá ọ wí mọ́.
“Kuoma to ma chalona mana gi ndalo mag Nowa kane akwongʼora ni pi mane oimo piny ok nochak obedie kendo. Omiyo koro asekwongʼora ni mirima ok nochak omaka kodu kendo, bende ok anachak adhawnu.
10 Bí a tilẹ̀ mi àwọn òkè ńlá tí a sì ṣí àwọn òkè kékeré nídìí, síbẹ̀síbẹ̀ ìfẹ́ àìkùnà mi fún ọ kì yóò yẹ̀ láéláé tàbí májẹ̀mú àlàáfíà ni a ó mú kúrò,” ni Olúwa, ẹni tí ó síjú àánú wò ọ́ wí.
Kata ka gode biro yiengni, kendo gode matindo ibiro muki, to herana kuomu mosiko ok noyiengi, bende singruokna mar kwe ok nogol,” Jehova Nyasaye man-gi kech kuomu owacho.
11 Ìwọ ìlú tí a pọ́n lójú, tí ìjì ń gbá kiri tí a kò sì tù nínú, Èmi yóò fi òkúta Tikuosi kọ́ ọ àti ìpìlẹ̀ rẹ pẹ̀lú safire.
“Yaye dala maduongʼ misando, ma ahiti oyiecho maonge ngʼama hoyo, abiro geri gi kite motegno, kendo miseni anager gi gik mabeyo.
12 Èmi yóò fi iyùn ṣe odi rẹ, àwọn ẹnu-ọ̀nà ni a ó fi ohun èlò dáradára fún, àti àwọn ògiri rẹ pẹ̀lú òkúta iyebíye.
Anager kuondeni mag gige lweny gi rubi, dhorangeyeni to naketie kite ma nengogi tek, kendo ohingani naketie kite mabeyo.
13 Gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ ni Olúwa yóò kọ́, àlàáfíà àwọn ọmọ rẹ yóò jẹ́ ńlá àti púpọ̀.
Nyithindi duto nopuonj gi Jehova Nyasaye kendo ginibed gi kwe maduongʼ.
14 Ní òdodo ni a ó fi ìdí rẹ kalẹ̀ ìwà ipá yóò jìnnà sí ọ o kò ní bẹ̀rù ohunkóhun, ìpayà la ó mú kúrò pátápátá; kò ní súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ.
Ibiro geri e tim makare: Ok nichak ine tij achuna; kendo onge gima iniluor. Bwok maduongʼ ibiro ter mabor kode; kendo ok ginisud machiegni kodi.
15 Bí ẹnikẹ́ni bá tilẹ̀ bá ọ jà, kò ní jẹ́ láti ọwọ́ mi; ẹnikẹ́ni tí ó bá bá ọ jà ni yóò túúbá fún ọ.
Kapo ni ngʼato omonji, to ok nobed ni an ema aore; to ngʼato angʼata momonji nochiwre e lweti.
16 “Kíyèsi i, èmi ni ó dá alágbẹ̀dẹ tí ń fẹ́ iná èédú iná tí ó sì ń mú ohun èlò wá tí ó bá iṣẹ́ rẹ mu. Èmi náà sì ni ẹni tí ó dá apanirun láti ṣe iṣẹ́ ibi;
“To ne, an ema ne achweyo jatheth mula, machwako chuma e mach, kendo loso gige lweny makare ne tijno. An ema asechweyo jaketh mabiro kelonegi chandruok;
17 kò sí ohun ìjà tí a ṣe sí ọ tí yóò lè ṣe nǹkan, àti gbogbo ahọ́n tí ó dìde sí ọ ní ìdájọ́ ni ìwọ ó dá ní ẹ̀bi. Èyí ni ogún àwọn ìránṣẹ́ Olúwa, èyí sì ni ìdáláre wọn láti ọ̀dọ̀ mi,” ni Olúwa wí.
onge gige lweny molosi ne in mano hinyi, kendo inilo buche duto modonjnie. Ma e pok ma jotich Jehova Nyasaye yudo, kendo ma bende e gweth ma asemiyou,” Jehova Nyasaye owacho.