< Isaiah 54 >
1 “Kọrin, ìwọ obìnrin àgàn, ìwọ tí kò tí ì bímọ rí; bú sí orin, ẹ hó fún ayọ̀, ẹ̀yin tí kò tí ì rọbí rí; nítorí pé púpọ̀ ni ọmọ àwọn obìnrin ìsọdahoro ju ti ẹni tí ó ní ọkọ,” ni Olúwa wí.
Yelusaleme! Di da aligime uda defele esalebe ba: i. Be wali di da gesami hea: musa: , amola hahawaneba: le wele sia: musa: dawa: Wali dia mano lalelegemu ili idi da uda amo egoa hame fisi ea mano ilia idi bagadewane baligimu.
2 Fẹ ibi àgọ́ rẹ lójú sí i, fẹ aṣọ àgọ́ rẹ kí ó gbòòrò sí i, má ṣe dá a dúró; sọ okùn rẹ di gígùn, mú òpó rẹ lágbára sí i.
Dia abula diasu amo bu bagade hamoma. Ea efe amo sedagimu amola ea ifa goge bugi amo bu gasa bagade hahamoma.
3 Nítorí ìwọ ó fẹ̀ sọ́tùn àti sí òsì; ìrandíran rẹ yóò jogún àwọn orílẹ̀-èdè, wọn yóò sì dó sí ahoro àwọn ìlú wọn.
Dia alalo defei la: ididili huluane amo mugululi bu bagade hamoma. Wali ga fi da dia sogega esala. Be dilia amo soge bu samogemu. Moilai wali amo ganodini dunu da hamedafa gala, amo da bu dunuga nabai dagoi ba: mu.
4 “Má ṣe bẹ̀rù, ìtìjú kò ní ṣubú lù ọ́. Má ṣe bẹ̀rù ìdójútì, a kì yóò kàn ọ́ lábùkù. Ìwọ yóò gbàgbé ìtìjú ìgbà èwe e rẹ, ìwọ kì yóò sì rántí ẹ̀gàn ìgba-opo rẹ mọ́.
Mae beda: ma! Di da gogosiasu bu hame ba: mu. Di da gaheabolo gawa fili baligi fa: su hamoi amo gogolemu. Amola di da didalo agoane esalebeba: le se bagade nabi, amo amola di da gogolemu.
5 Nítorí Ẹlẹ́dàá rẹ ni ọkọ rẹ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀ Ẹni Mímọ́ Israẹli ni Olùràpadà rẹ; a sì ń pè é ní Ọlọ́run gbogbo ayé.
Dia Hahamosu dunu da dima digua agoane ba: mu. Ea dio da Hina Gode Bagadedafa. Isala: ili fi ilia Hadigi Gode da di gaga: mu. Bai E da osobo bagade amoma Hina bagade.
6 Olúwa yóò pè ọ́ padà àfi bí ẹni pé obìnrin tí a kọ̀sílẹ̀ tí a sì bà lọ́kàn jẹ́ obìnrin tí a fẹ́ ní ọ̀dọ́, tí a sì wá jákulẹ̀,” ni Olúwa wí.
Isala: ili! Di da gaheabolo lai uda amo egoa da e fisiagaiba: le, se bagade naba, amo defele ba: sa. Be Hina Gode da Ema bu misa: ne, dima wele sia: sa.
7 “Fún ìgbà díẹ̀ ni mo kọ̀ ọ́ sílẹ̀, ṣùgbọ́n pẹ̀lú ọkàn ìyọ́nú èmi yóò mú ọ padà wá.
E da amane sia: sa, “Na da fonobahadidafa wadofamusu di fisiagai. Be Na da bagade asigiwane di bu lamu.
8 Ní ríru ìbínú. Mo fi ojú pamọ́ fún ọ fún ìṣẹ́jú kan, ṣùgbọ́n pẹ̀lú àánú àìnípẹ̀kun Èmi yóò síjú àánú wò ọ́,” ni Olúwa Olùdáǹdè rẹ wí.
Na da ougiba: le, fonobahadidafa dima Na baligi olelei. Be wali Na da Na asigidafa hou mae fisili, dima olelelalumu.” Hina Gode, dia gaga: su dunu, da amane sia: sa.
9 “Sí mi, èyí dàbí i àwọn ọjọ́ Noa, nígbà tí mo búra pé àwọn omi Noa kì yóò tún bo ilẹ̀ ayé mọ́. Bẹ́ẹ̀ ni nísinsin yìí mo ti búra láti má ṣe bínú sí ọ, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò bá ọ wí mọ́.
“Nowa: ea esoga Na da osobo bagade amo hano bagadega bu hame dedeboma: ne ilegele sia: i. Amola wali Na da dima bu hame ougimu amo Na da ilegele sia: sa. Na da dima bu gagabole hame sia: mu, amola dima se hame imunu.
10 Bí a tilẹ̀ mi àwọn òkè ńlá tí a sì ṣí àwọn òkè kékeré nídìí, síbẹ̀síbẹ̀ ìfẹ́ àìkùnà mi fún ọ kì yóò yẹ̀ láéláé tàbí májẹ̀mú àlàáfíà ni a ó mú kúrò,” ni Olúwa, ẹni tí ó síjú àánú wò ọ́ wí.
Goumi ilia da ugugusia amola agolo da mugululi hamedafa ba: sea, be Na dima asigidafa hou da mae mugululi, dialalalumu. Na dima olofosu ima: ne ilegei, amo Na da hame gogolemu.” Hina Gode da amane sia: sa. E da dima asigidafa gala.
11 Ìwọ ìlú tí a pọ́n lójú, tí ìjì ń gbá kiri tí a kò sì tù nínú, Èmi yóò fi òkúta Tikuosi kọ́ ọ àti ìpìlẹ̀ rẹ pẹ̀lú safire.
Hina Gode da amane sia: sa, “Yelusaleme! Di da se bagade naba. Disu di gaga: mu da hame dawa: , amola eno dunu ilia dia dogo hame denesisa. Na da igi ida: iwane amoga dia bai bu gagumu.
12 Èmi yóò fi iyùn ṣe odi rẹ, àwọn ẹnu-ọ̀nà ni a ó fi ohun èlò dáradára fún, àti àwọn ògiri rẹ pẹ̀lú òkúta iyebíye.
Na da dia diasu gado gagagula heda: i amo ‘lubi’ igi amoga gagumu. Dia logo ga: su, Na da igi amo da lalu agoane hadigi gala, amoga gagumu. Amola gagoi dobea da di sisiga: sa, amo Na da igi ida: iwanedafa amoga gagumu.
13 Gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ ni Olúwa yóò kọ́, àlàáfíà àwọn ọmọ rẹ yóò jẹ́ ńlá àti púpọ̀.
Na Nisu da dia fi dunuma olelemu. Amola Na da ilima olofosu amola bagade gagui hou imunu.
14 Ní òdodo ni a ó fi ìdí rẹ kalẹ̀ ìwà ipá yóò jìnnà sí ọ o kò ní bẹ̀rù ohunkóhun, ìpayà la ó mú kúrò pátápátá; kò ní súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ.
Dilia da moloidafa hou lalegaguiba: le, gasawane lelumu. Dilia da gaga: i dagoi ba: beba: le, eno dunu da dilima se hame imunu amola dilia da beda: su hame ba: mu.
15 Bí ẹnikẹ́ni bá tilẹ̀ bá ọ jà, kò ní jẹ́ láti ọwọ́ mi; ẹnikẹ́ni tí ó bá bá ọ jà ni yóò túúbá fún ọ.
Nowa da dilima doagala: sea, ilia da Na hanaiga hame hamomu. Be nowa da dilima gegesea da dafamu.
16 “Kíyèsi i, èmi ni ó dá alágbẹ̀dẹ tí ń fẹ́ iná èédú iná tí ó sì ń mú ohun èlò wá tí ó bá iṣẹ́ rẹ mu. Èmi náà sì ni ẹni tí ó dá apanirun láti ṣe iṣẹ́ ibi;
Na da ouli hahamosu dunu amo da lalu didili ouli gegesu liligi hamosa, Na da amo dunu hahamosa. Amola Na da dadi gagui dunu e da amo gegesu liligiga gegenana, Na da amo amola hahamosa.
17 kò sí ohun ìjà tí a ṣe sí ọ tí yóò lè ṣe nǹkan, àti gbogbo ahọ́n tí ó dìde sí ọ ní ìdájọ́ ni ìwọ ó dá ní ẹ̀bi. Èyí ni ogún àwọn ìránṣẹ́ Olúwa, èyí sì ni ìdáláre wọn láti ọ̀dọ̀ mi,” ni Olúwa wí.
Be gegesu liligi afae da dilima se imunu hamedei ba: mu. Nowa da dilima diwaneya udidisia, dilia da ilima ilia sia: hedofamusa: bu adole imunu dawa: mu. Na da Na hawa: hamosu dunu gaga: mu amola hasalasu hou ilima imunu,” Hina Gode da amane sia: i dagoi.