< Isaiah 49 >

1 Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin erékùṣù: gbọ́ èyí, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè jíjìnnà réré: kí a tó bí mi Olúwa ti pè mí; láti ìgbà bíbí mi ni ó ti dá orúkọ mi.
Winjauru un joma odak e dho nembe, winjuru un pinje man mabor: Kane pok onywola Jehova Nyasaye ne oluonga koa e nywolna ne oluongo nyinga.
2 Ó ṣe ẹnu mi bí idà tí a pọ́n, ní abẹ́ òjìji ọwọ́ rẹ̀ ni ó ti pa mí mọ́: ó ṣe mí ní ọfà tí a ti dán, ó sì fi mí pamọ́ sínú àpò rẹ̀.
Ne omiyo lewa obedo ka ligangla mabith, e bwo tipo mar lwete ne opanda; ne omiyo abedo ka asere moywe maler kendo ne opanda e olalone.
3 Ó sọ fún mi pé, “Ìránṣẹ́ mi ni ìwọ í ṣe, Israẹli nínú ẹni tí n ó ti fi ògo mi hàn.”
Ne owachona niya, “In e jatichna, Israel, kuomi ema abiro nyisoe duongʼ mara.”
4 Ṣùgbọ́n èmi sọ pé, “Mo ti ṣe wàhálà lórí asán; mo ti lo gbogbo ipá mi lórí asán àti ìmúlẹ̀mófo. Síbẹ̀síbẹ̀ ohun tí ó tọ́ sí mi ṣì wà lọ́wọ́ Olúwa, èrè mi sì ń bẹ pẹ̀lú Ọlọ́run mi.”
To ne awacho ni, “Asetiyo matek kayiem nono; aseketho tekra kayiem nono. Kata kamano pokna ni e lwet Jehova Nyasaye kendo michna Nyasacha ema nigo.”
5 Nísinsin yìí Olúwa wí pé ẹni tí ó mọ̀ mí láti inú wá láti jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ láti mú Jakọbu padà tọ̀ mí wá àti láti kó Israẹli jọ sọ́dọ̀ ara rẹ̀, nítorí pé a bọ̀wọ̀ fún mi ní ojú Olúwa Ọlọ́run mi sì ti jẹ́ agbára mi,
To koro Jehova Nyasaye wacho kama; jal mane ochweya e ich mondo abed jatichne, mondo adwok joka Jakobo kuome kendo achok jo-Israel ire, nimar aseyudo duongʼ e wangʼ Jehova Nyasaye, kendo Nyasacha ema osebedo tekrena.
6 Òun wí pé: “Ó jẹ́ ohun kékeré fún ọ láti jẹ́ ìránṣẹ́ mi láti mú ẹ̀yà Jakọbu padà bọ̀ sípò àti láti mú àwọn ti Israẹli tí mo ti pamọ́. Èmi yóò sì fi ọ́ ṣe ìmọ́lẹ̀ fún àwọn kèfèrí, kí ìwọ kí ó lè mú ìgbàlà mi wá sí òpin ilẹ̀ ayé.”
Owacho ni: “En gima tin ahinya mondo ibed jatichna kata mondo iduog dhood joka Jakobo, kendo mondo iduog jo-Israel manok mane odongʼ. Abiro miyo ibed ler mar ogendini, mondo iter wach warruokna e tunge piny duto.”
7 Ohun tí Olúwa wí nìyìí, Olùdáǹdè àti Ẹni Mímọ́ Israẹli— sí ẹni náà tí a gàn tí a sì kórìíra lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè, sí ìránṣẹ́ àwọn aláṣẹ: “Àwọn ọba yóò rí ọ wọn yóò sì dìde sókè, àwọn ọmọ ọba yóò rí i wọn yóò sì wólẹ̀, nítorí Olúwa ẹni tí í ṣe olóòtítọ́, Ẹni Mímọ́ Israẹli tí ó ti yàn ọ́.”
Ma e gima Jehova Nyasaye, ma Jares ji kendo Ngʼat Maler mar Israel wacho, ne ngʼat mane ogendini ochayo kendo ma en misumba jotend piny: “Ruodhi nochungʼni malo koneni, kendo jotelo koneno ma to nopodhni auma, nikech Jehova Nyasaye, jal ma ja-adiera ma en Ngʼat Maler mar Israel ema oseyieri.”
8 Ohun tí Olúwa wí nìyìí: “Ní àkókò ojúrere mi, èmi yóò dá ọ lóhùn, àti ní ọjọ́ ìgbàlà, èmi yóò ràn ọ́ lọ́wọ́; Èmi yóò pa ọ́ mọ́, n ó sì ṣe ọ́ láti jẹ́ májẹ̀mú fún àwọn ènìyàn, láti mú ilẹ̀ padà bọ̀ sípò àti láti ṣe àtúnpín ogún rẹ̀ tí ó ti dahoro,
Ma e gima Jehova Nyasaye wacho, “E ndalona mag kech abiro dwoko kwayoni, chutho ne akonyi e odiechiengʼ mar warruok; abiro riti mi ami ibed ngʼama kelo winjruok e kinda gi ji mondo ires piny, mi ipog ji kuonde ma yande odongʼ gunda,
9 láti sọ fún àwọn ìgbèkùn pé, ‘Ẹ jáde wá,’ àti fún àwọn tí ó wà nínú òkùnkùn pé, ‘Ẹ gba òmìnira!’ “Wọn yóò máa jẹ ní ẹ̀bá ọ̀nà àti koríko tútù lórí òkè aláìléwéko.
kendo iwachne joma ni e twech ni, ‘Wuoguru oko,’ to joma ni e mudho ni, ‘Beduru thuolo!’ “Gibiro chiemo e bath yo kendo giniyud kuonde kwath e gode matindo.
10 Ebi kì yóò pa wọ́n bẹ́ẹ̀ ni òǹgbẹ kì yóò gbẹ wọ́n, tàbí kí ooru inú aṣálẹ̀ tàbí oòrùn kí ó pa wọ́n. Ẹni tí ó ṣàánú fún wọn ni yóò máa tọ́ wọn, tí yóò sì mú wọn lọ sí ibi orísun omi.
Kech ok nokagi kata riyo ok nologi, bende liet mar kama otimo ongoro, kata chiengʼ marieny makech ok nomigi olo. Jal ma chunye opongʼ gi kech, ema notelnigi mi tergi kuonde sokni mag pi.
11 Èmi yóò sọ gbogbo àwọn òkè ńlá mi di ojú ọ̀nà àti gbogbo òpópónà mi ni a ó gbé sókè.
Abiro loko godena duto yore kendo anabug yorena madongo duto maber.
12 Kíyèsi i, wọn yóò wá láti ọ̀nà jíjìn àwọn díẹ̀ láti àríwá àti àwọn díẹ̀ láti ìwọ̀-oòrùn, àwọn díẹ̀ láti ẹkùn Siene.”
To ne, ginibi ka gia mabor; moko kawuok yo nyandwat, moko kawuok yo yimbo, moko to nowuogi e gwenge mag Aswan.”
13 Ẹ hó fún ayọ̀, ẹyin ọ̀run; yọ̀, ìwọ ilẹ̀ ayé; bú sórin, ẹ̀yin òkè ńlá! Nítorí Olúwa tu àwọn ènìyàn rẹ̀ nínú yóò sì ṣàánú fún àwọn ẹni tí a ń pọ́n lójú.
Go koko nikech mor, yaye polo, bed gi ilo, yaye piny, weruru matek, un gode! Nimar Jehova Nyasaye kweyo chuny joge kendo obiro bedo gi kech ne joge machandore.
14 Ṣùgbọ́n Sioni sọ pé, “Olúwa ti kọ̀ mí sílẹ̀, Olúwa ti gbàgbé è mi.”
To Sayun nowacho niya, “Jehova Nyasaye osejwangʼa; kendo Ruoth Nyasaye wiye osewil koda.”
15 “Ǹjẹ́ abiyamọ ha le gbàgbé ọmọ ọmú rẹ̀ kí ó má sì ṣàánú fún ọmọ rẹ̀ tí ó ti bí? Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun le gbàgbé, Èmi kì yóò gbàgbé rẹ!
“To bende dhako wiye diwil gi nyathi modhodho mi ok obedo gi kech e kothe mane onywolo. Kata ka dipo ni wiye nyalo wil, An to wiya ok nowil kodi.
16 Kíyèsi i, mo ti kọ ọ́ sí àtẹ́lẹwọ́ mi ògiri rẹ wà níwájú mi nígbà gbogbo.
Ne, asendiko nyingi ei lweta kendo isiko ka ineno anena e wangʼa.
17 Àwọn ọmọ rẹ ti kánjú padà, àti àwọn tí ó sọ ọ́ dahoro ti padà lẹ́yìn rẹ.
Yawuoti noreti kaduogo iri kendo jogo manoyako gigi noringi kaduogo iri.
18 Gbójú rẹ sókè kí o sì wò yíká; gbogbo àwọn ọmọkùnrin rẹ kórajọ wọ́n sì wá sọ́dọ̀ rẹ. Níwọ́n ìgbà tí mo bá wà láààyè,” ni Olúwa wí, “Ìwọ yóò wọ gbogbo wọ́n gẹ́gẹ́ bí ohun ọ̀ṣọ́; ìwọ yóò wọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ bí ìyàwó.
Tingʼ wangʼi malo kendo ingʼi koni gi koni: mondo ine kaka yawuoti chokore kaduogo iri.” Jehova Nyasaye wacho niya, “Akwongʼora gi nyinga awuon ni nyithindi nochal gi thiwni madhako rwako kata ka law maber ma miaha rwako.
19 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a tí run ọ́, a sì sọ ọ́ di ahoro tí gbogbo ilẹ̀ rẹ sì di ìparun, ní ìsinsin yìí, ìwọ yóò kéré jù fún àwọn ènìyàn rẹ, bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ó jẹ ọ́ run ni yóò wà láti ọ̀nà jíjìn réré.
“Kata obedo ni osetieki midongʼ gunda kendo pinyi odongʼ nono, to koro ibiro yudo ni pinyi odoko matin ma ok oromo jogi dakie, kendo jogo mane otieki biro bedo kodi mabor.
20 Àwọn ọmọ tí a bí ní àkókò ọ̀fọ̀ rẹ yóò sọ ní etígbọ̀ọ́ rẹ, ‘Ibi yìí ti kéré jù fún wa; ẹ fún wa láyè sí i tí a ó máa gbé.’
Nyithindo mane inywolo ka in e chandruok nowachni kiwinjo ni, Kaeni tin-nwa; dwarnwa kama lach mondo wadagie.
21 Nígbà náà ni ìwọ yóò sọ ní ọkàn rẹ pé, ‘Ta ló bí àwọn yìí fún mi? Mo ti ṣọ̀fọ̀ mo sì yàgàn; a sọ mi di àtìpó a sì kọ̀ mí sílẹ̀. Ta ló wo àwọn yìí dàgbà? A fi èmi nìkan sílẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí níbo ni wọ́n ti wá?’”
Eka inipenjri e chunyi ni, ‘En ngʼa mane onywolona jogi? Ne an gi kuyo kendo ne an migumba, ne otera e twech kendo ojwangʼa. En ngʼa manopidhogi? Ne adongʼ kenda, to jogi to oa kure?’”
22 Ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nìyìí, “Kíyèsi i, Èmi yóò ké sí àwọn aláìkọlà, Èmi yóò gbé àsíá mi sókè sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn; wọn yóò kó àwọn ọmọkùnrin yín wá ní apá wọn wọn yóò sì gbé àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin ní èjìká wọn.
Ma e gima Jehova Nyasaye Manyalo Gik Moko Duto wacho: “Winji, abiro luongo Ogendini, abiro chungo bandecha ne oganda kaka ranyisi, gibiro kelo yawuoti ka gitingʼogi e badgi kendo ginikel nyigi ka gitingʼogi e gokgi.
23 Àwọn ọba ni yóò jẹ́ alágbàtọ́ baba fún ọ, àwọn ayaba wọn ni yóò sì jẹ́ ìyá-alágbàtọ́. Wọn yóò foríbalẹ̀ ní iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ojú wọn dídàbolẹ̀; wọn yóò máa lá erùpẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa; gbogbo àwọn tí wọ́n ní ìrètí nínú mi ni a kì yóò jákulẹ̀.”
Ruodhi ema nobed kaka wuoneu kendo mond ruodhi ema nobed kaka mineu ma ritou. Ginikulre auma e nyimu ka wengegi ngʼiyo piny; kendo gininangʼ buru manie tiendu. Eka unungʼe ni An e Jehova Nyasaye kendo joma oketo genogi kuoma ok noyud wichkuot.”
24 Ǹjẹ́ a le gba ìkógun lọ́wọ́ jagunjagun, tàbí kí á gba ìgbèkùn lọ́wọ́ akíkanjú?
Bende dima jolweny maroteke gik ma giseyako, koso dires joma otwe e lwet ngʼama kwiny?
25 Ṣùgbọ́n ohun tí Olúwa wí nìyìí: “Bẹ́ẹ̀ ni, a ó gba àwọn ìgbèkùn lọ́wọ́ àwọn jagunjagun, àti ìkógun lọ́wọ́ àwọn akíkanjú; ẹni tí ó bá ọ jà ni èmi ó bá jà, àti àwọn ọmọ rẹ ni èmi ó gbàlà.
To ma e gima Jehova Nyasaye wachoni: “Ee, joma otwe inyalo gol e lwet jolweny maroteke, kendo ngʼama omaki inyalo gamo e lwet joma kwiny; anaked gi jogo makedo kodu, kendo anares nyithindu.
26 Èmi yóò mú kí àwọn aninilára rẹ̀ jẹ ẹran-ara wọn; wọn yóò mu ẹ̀jẹ̀ ara wọn yó bí ẹni mu wáìnì. Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ pé, Èmi, Olúwa, èmi ni Olùgbàlà rẹ, Olùdáǹdè rẹ, Alágbára kan ṣoṣo ti Jakọbu.”
Abiro miyo joma sandou nocham ringregi giwegi mi anami gimer gi rembgi ka joma omadho kongʼo. Eka koth dhano duto manie piny nongʼe ni an Jehova Nyasaye e Jawarni, Jaresni kendo Nyasaye Maratego mar Jakobo.”

< Isaiah 49 >