< Isaiah 48 >
1 “Tẹ́tí sí èyí, ìwọ ilé e Jakọbu, ìwọ tí a ń pè pẹ̀lú orúkọ Israẹli tí o sì wá láti ẹ̀ka Juda, ìwọ tí ò ń búra ní orúkọ Olúwa tí o sì ń pe Ọlọ́run Israẹli ṣùgbọ́n kì í ṣe ní òtítọ́ àti òdodo,
Isala: ili fi dunu! Yuda egaga fi dunu! Nabima! Dilia da Hina Gode Ea Dioba: le sia: sa, amola dilia Isala: ili Gode Ema nodone sia: ne gadosa sia: sa. Be dilia sia: dafawaneyale hame sia: sa.
2 ìwọ tí ò ń pe ara rẹ ní ọmọ ìlú mímọ́ n nì tí o sì gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run Israẹli— Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
Be dilia gasa fili, dilia da Hadigi moilai bai bagade amo ea esalebe dunu, amola dilia da Isala: ili Gode (Ea Dio da Hina Gode Bagadedafa) amo dili fidima: ne dafawaneyale dawa: , amane sia: sa.
3 Èmi sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn nǹkan ti tẹ́lẹ̀ lọ́jọ́ tó ti pẹ́, ẹnu mi ló ti kéde wọn, mo sì sọ wọ́n di mí mọ̀; lẹ́yìn náà lójijì mo gbé ìgbésẹ̀, wọ́n sì wá sí ìmúṣẹ.
Hina Gode da Isala: ili fi ilima amane sia: sa, “Na da musa: hemonega hobea misunu hou ba: la: lu, dilima sia: i dagoi. Amalalu, hedolodafa amo hou dafawane ba: ma: ne, Na da hamoi dagoi.
4 Nítorí mo mọ bí ẹ ti jẹ́ olórí kunkun tó; àwọn iṣan ọrùn yín sì jẹ́ irin; bẹ́ẹ̀ ni iwájú yín idẹ ni.
Dilia da hame nabasu hou, amola gasa fi hou hamomu, amo Na dawa: i galu. Dilia da ouli agoane selefamu hamedei, amola balase defele ga: nasi bagade hamomu, Na da dawa: i galu.
5 Nítorí náà mo ti sọ nǹkan wọ̀nyí fún ọ ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́; kí wọn ó tó ṣẹlẹ̀ mo ti kéde wọn fún un yín tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ kò fi lè sọ pé, ‘Àwọn ère mi ló ṣe wọ́n; àwọn ère igi àti òrìṣà irin ló fọwọ́sí i.’
Amaiba: le, Na da dilima hobea misunu hou amo hemonega ba: beba: le, sia: i dagoi. Dilia da dilia loboga hamoi ‘gode’ da dilia hou hahamoi dagoi, amo dilia da sia: sa: besa: le, Na da amo hou da hobea misunu, hemonega sia: i dagoi.
6 Ìwọ ti gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí; wo gbogbo wọn. Ǹjẹ́ o kò nígbà wọ́n bí? “Láti ìsinsin yìí lọ, Èmi yóò máa sọ fún ọ nípa nǹkan tuntun, àwọn nǹkan tí ó fi ara sin tí ìwọ kò mọ̀.
Be wali Na ba: la: lusu sia: i liligi huluane da hamoi dagoi ba: sa. Amola amo ba: la: lusu liligi da dafawane, dilia da wali sia: sa. Wali Na da gaheabolo hou, Na da musa: wamolegei amo hobea misunu, Na da dilima olelemu.
7 A dá wọn ní àkókò yìí kì í ṣe láti ìgbà pípẹ́ ìwọ kò tí ì gbọ́ nípa wọn títí di òní. Nítorí náà, ìwọ kò lè sọ pé, ‘Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ nípa wọn.’
Na da wali hamonanebeba: le, amo hou da doaga: i. Agoanewane hou da musa: hamedafa ba: i. Amo hou da musa: ba: i ganiaba, dilia da amo hou huluane dawa: dagoi, dilia da sia: na: noba.
8 Ìwọ a ha ti gbọ́ tàbí ó ti yé ọ bí láti ìgbà àtijọ́ etí kò ti di yíyà. Ǹjẹ́ mo mọ̀ bí o ti jẹ́ alárékérekè tó; a ń pè ọ́ ní ọlọ̀tẹ̀ láti ìgbà ìbí rẹ.
Be dilia hou da moloi hame, Na dawa: i galu. Dilia da eso huluane seselesu dunu agoane esala, dunu huluane da dawa: Amaiba: le, dilia da Na hobea hamomu hou hamedafa nabi.
9 Nítorí orúkọ ara mi, mo dáwọ́ ìbínú mi dúró; nítorí ìyìn ara mi, mo fà á sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ, kí a má ba à ké ọ kúrò.
Dunu da Na Dio amoma nodoma: ne, Na da Na ougi dili mae wadela: lesima: ne gagusa. Na da dili hame gugunufinisimu.
10 Wò ó, èmi ti tún ọ ṣe, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe bí i fàdákà; Èmi ti dán ọ wò nínú ìléru ìpọ́njú.
Na da se nabasu hou lalu agoane amo ganodini, silifa ea hou adoba: su agoane, dilia hou adoba: su. Be dilia da hamedei dunu, amo Na da ba: i dagoi.
11 Nítorí orúkọ mi, nítorí orúkọ mi, mo ṣe èyí. Báwo ni mo ṣe lè jẹ́ kí a ba orúkọ mi jẹ́. Èmi kì yóò fi ògo mi fún ẹlòmíràn.
Be amo hou Na da Na Dio gaguia gadoma: ne fawane hamoi. Na Dio wadela: lesima: ne, Na da hamedafa ba: mu. Amola eno dunu da Na Hadigi gilisili lamusa: , Na da logo hamedafa doasimu. Na Hadigi da Na Nisu fawane gagusa.”
12 “Tẹ́tí sí mi, ìwọ Jakọbu Israẹli ẹni tí mo pè. Èmi ni ẹni náà; Èmi ni ẹni àkọ́kọ́ àti ẹni ìgbẹ̀yìn.
Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili fi dunu, Na da dili Nama misa: ne wele sia: nanu, ilegei dagoi. Na sia: nabima! Na da Gode amo Hemosu amola Dagosu, eno hame, Na da Godedafa.
13 Ọwọ́ mi pàápàá ni ó fi àwọn ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀, àti ọwọ́ ọ̀tún mi ni ó tẹ àwọn ọ̀run; nígbà tí mo pè wọ́n, gbogbo wọn dìde sókè papọ̀.
Na da osobo bagade ea bai amola mu amo Na loboga hamoi. Na da osobo bagade amola mu Nama misa: ne sia: sea, ilia da hedolo Nama misini gousa: sa.
14 “Gbogbo yín, ẹ péjọ kí ẹ sì gbọ́. Ta nínú wọn ni ó ti sọ nǹkan wọ̀nyí. Olúwa ti fẹ́ ẹ, yóò sì ṣe ìfẹ́ rẹ̀ ní Babiloni, apá rẹ̀ ni yóò sì wà ní ará àwọn ará Kaldea.
Dilia huluane gilisima amola nabima! Na ilegei dunu da Na hanai defele Ba: bilone doagala: mu. Eno ‘gode’ liligi afae da amo hou ba: la: lumu hamedei.
15 Èmi, àní Èmi ló ti sọ̀rọ̀; bẹ́ẹ̀ ni, mo ti pè é. Èmi yóò mú un wá, òun yóò sì ṣe àṣeyọrí nínú ìrìnàjò rẹ̀.
Na fawane da ema sia: i, amola ema misa: ne sia: i. Na da e gadili masa: ne oule asi, amola e didili hamoma: ne, Na fawane da ea logo fodoi.
16 “Ẹ súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi kí ẹ sì dẹtí sí èyí: “Láti ìgbà ìkéde àkọ́kọ́ èmi kò sọ̀rọ̀ ní ìkọ̀kọ̀; ní àsìkò tí ó sì ṣẹlẹ̀, Èmi wà níbẹ̀.” Àti ní àkókò yìí, Olúwa Olódùmarè ni ó ti rán mi, pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ̀.
Wali, Nama gadenena misa, amola Na sia: nabima. Hemonega amola fa: no Na da mae wamolegele, sia: moloidafa sia: i. Amola Na sia: sia: i da Na hamobeba: le, dafawane hamoi ba: i.” (Wali Hina bagade Gode Ouligisudafa da Ea gasa nama ianu, na asunasi dagoi.)
17 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, Olùdáǹdè rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli: “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, tí ó kọ́ ọ ní ohun tí ó dára fún ọ, tí ó tọ́ ọ ṣọ́nà tí ó yẹ kí o máa rìn.
Isala: ili Hadigi Gode, dilia Gaga: su, da amane sia: sa, “Na da Hina Gode, dilia Gode! Na da dilia hou noga: ma: ne dilima olelesa amola dilia noga: le masa: ne logo olelesa.
18 Bí ó bá ṣe pé ìwọ bá ti tẹ́tí sílẹ̀ sí àṣẹ mi, àlàáfíà rẹ kì bá ti dàbí ì ti odò, àti òdodo rẹ bí ìgbì Òkun.
Dilia da na sia: noga: le nabi ganiaba, dilima hahawane hou hano da hafoga: su hame dawa: , amo defele dilima doaga: la: loba. Amola hasalasu hou hano wayabo bagade gafului da hano bega: doaga: sa, amo defele dilima doaga: la: loba.
19 Àwọn ọmọ rẹ ìbá ti dàbí iyanrìn, àwọn ọmọ yín bí i hóró ọkà tí a kò lè kà tán; orúkọ wọn ni a kì yóò ké kúrò tàbí kí a pa wọ́n run níwájú mi.”
Amola dilia agoane hamoi ganiaba, diligaga fi ilia idi da sa: iboso ea idi defele ba: la: loba amola ilia hamedafa gugunufinisimu Na da hamonana: noba.”
20 Fi Babeli sílẹ̀, sá fún àwọn ará Babeli, ṣe ìfilọ̀ èyí pẹ̀lú ariwo ayọ̀ kí o sì kéde rẹ̀. Rán an jáde lọ sí òpin ilẹ̀ ayé; wí pé, “Olúwa ti dá ìránṣẹ́ rẹ̀ Jakọbu nídè.”
Dilia! Ba: bilone soge fisili, hahawane gadili masa. Amo sia: hahawane wele sia: ma. Dunu huluane nabima: ne, hahawane agoane sia: mu, “Hina Gode da Ea hawa: hamosu dunu fi Isala: ili, amo gaga: i dagoi.”
21 Òrùngbẹ kò gbẹ wọ́n nígbà tí ó kó wọn kọjá nínú aginjù; ó jẹ́ kí omi ó sàn fún wọn láti inú àpáta; ó fọ́ àpáta omi sì tú jáde.
Hina Gode da Ea fi dunu amo gia: i bagade hafoga: i soge amo ganodini oule ahoanoba, ilia da hano hanai hame ba: i. Ea hamobeba: le, hano da igi amoga yogosa: i. E da igi oudahida: le, hano da amo ganodini misi.
22 “Kò sí àlàáfíà,” ni Olúwa wí, “Fún àwọn ìkà.”
Wadela: i hamosu dunu da gaga: su hame ba: mu,” Hina Gode da amane sia: sa.