< Isaiah 47 >

1 “Sọ̀kalẹ̀, jókòó nínú eruku, wúńdíá ọmọbìnrin Babeli; jókòó ní ilẹ̀ láìsí ìtẹ́, ọmọbìnrin àwọn ará Babeli. A kì yóò pè ọ́ ní aláìlókun àti ẹlẹgẹ́ mọ́.
Hina Gode da fedege sia: amane sia: sa, “Ba: bilone! Dia fisu amo fisili, osoboga aligila sa: ili amola osobo su amoga fima. Di da musa: a:fini dunu hame dawa: digi agoane galu. Di da musa: moilai bai bagade, eno dunuga hame hasanasi agoane galu. Be wali dia da asaboi amola noga: iwane ba: su hame gala. Di da bu udigili hawa: hamosu dunu agoai hamoi dagoi.
2 Mú òkúta-ọlọ kí o sì lọ ìyẹ̀fun; mú ìbòjú rẹ kúrò. Ká aṣọ ẹsẹ̀ rẹ sókè, ká aṣọ itan, kí o sì la odò wọ̀n-ọn-nì kọjá.
Widi goudasu igi sisiga: su bebesoma! Widi goudama! Dia abula sawa: figisu fadegama! Dia abula sosone noga: idafa gisa: ma! Hano degemusa: , dia gaeya gogomone gadoma.
3 Ìhòhò rẹ ni a ó sí síta àti ìtìjú rẹ ni a ó ṣí sílẹ̀. Èmi yóò sì gba ẹ̀san, Èmi kì yóò sì dá ẹnìkan sí.”
Dunu da dia da: i nabado ba: mu. Dia da fonoboi dagoi amola ilia da dia gogosiasu ba: mu. Na da dabe imunu amola enoga Na logo hedofamu da hamedei.”
4 Olùràpadà wa Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀ òun ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Isala: ili ilia Hadigi Gode da ninia hahawane dogolegele masa: ne, logo doasisa. Ea dio da Hina Gode Bagadedafa.
5 “Jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, lọ sínú òkùnkùn, ọmọbìnrin àwọn ará Babeli; a kì yóò pè ọ́ ní ọbabìnrin àwọn ilẹ̀ ọba mọ́.
Hina Gode da Ba: bilone fi ilima amane sia: sa, “Di ouiya: le gasi ganodini fima. Musa: ilia da di da fifi asi gala huluane ilima hina bagade uda, ilia sia: i. Be agoane bu hame sia: mu.
6 Inú bí mi sí àwọn ènìyàn mi tí mo sì ba ogún mi jẹ́, mo fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́, Ìwọ kò sì síjú àánú wò wọ́n. Lórí àwọn arúgbó pẹ̀lú ní o gbé àjàgà tí ó wúwo lé.
Na da Na fi ilima ougi galu. Na da ilima asigi hou fisili, ilia da Na fi hame defele ilima hamosu. Di, Ba: bilone, ilima hasanasima: ne, Na da dia logo doasi. Di da ilima hame asigi. Dia da dunu huluane amola da: i hamoi dunu ilima mae asigili, ili se nabima: ne, gasa fi agoane hamoi.
7 Ìwọ wí pé, ‘Èmi yóò tẹ̀síwájú títí láé— ọbabìnrin ayérayé!’ Ṣùgbọ́n ìwọ kò kíyèsi nǹkan wọ̀nyí tàbí kí o ronú nípa ohun tí ó lè ṣẹlẹ̀.
Di da eso huluane hina bagade uda agoane esalumusa: dawa: i gala. Be di da dia hou hamobe, amola fa: no misunu hou hame dawa: i.
8 “Nísinsin yìí, tẹ́tí sílẹ̀, ìwọ oníwọ̀ra ẹ̀dá tí o kẹ̀tẹ̀ǹfẹ̀ nínú ààbò rẹ tí o sì ń sọ fún ara rẹ pé, ‘Èmi ni, kò sì ṣí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi. Èmi kì yóò di opó tàbí kí n pàdánù àwọn ọmọ.’
Ba: bilone! Hahawane hedesu hou hanai dunu! Nabima! Di da hahawane gagili sali dagoi dawa: lala. Dia da Gode defele, gasa bagadedafa esala, amola osobo bagadega eno fi di defele hame esala dawa: lala. Di da didalo hamone, amola dia mano huluane fisimu amo hamedafa dawa: i galu.
9 Méjèèjì yìí ni yóò wá sórí rẹ láìpẹ́ jọjọ, ní ọjọ́ kan náà: pípàdánù ọmọ àti dídi opó. Wọn yóò wá sórí rẹ ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́, pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn ìṣe oṣó rẹ àti àwọn èpè rẹ tí ko lágbára.
Be hedolodafa eso afadafa amoga, amo hou aduna da dima doaga: mu. Di da fefedoasu hou bagade hamomu, be digua amola mano fisimu.
10 Ìwọ ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ìwà ìkà rẹ ó sì ti wí pé, ‘Kò sí ẹni tí ó rí mi?’ Ọgbọ́n àti òye rẹ ti ṣì ọ́ lọ́nà nígbà tí o wí fún ara rẹ pé, ‘Èmi ni, kò sí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi.’
Dia da wadela: i hou hamobeba: le, disu da defele dawa: i galu. Dia hou da enoga ba: mu da hamedei agoane dawa: i galu. Dia da dia bagade dawa: su hou amoma fa: no bobogebeba: le, giadofale asi. Di da dima amane sia: i, “Na da Gode. Eno fi na defele da hame esala.”
11 Ìparun yóò dé bá ọ bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kì yóò mọ ọ̀nà láti ré e kúrò. Àjálù kan yóò ṣubú lù ọ́ tí o kì yóò le è fi ètùtù ré kúrò; òfò kan tí o kò le faradà ni yóò wá lójijì sí oríì rẹ.
Di da wadela: lesi dagoi ba: mu. Amola dia fefedoasu hou da dia dafasu gaga: mu gogolei. Wadela: su hou, amo di da hamedafa dawa: i galu, da dima doaga: mu.
12 “Tẹ̀síwájú nígbà náà, pẹ̀lú àfọ̀ṣẹ rẹ àti pẹ̀lú ìwà oṣó rẹ gbogbo, tí o ti ń ṣiṣẹ́ fún láti ìgbà èwe rẹ wá. Bóyá o le è ṣàṣeyọrí, bóyá o le è dá rúgúdù sílẹ̀.
Defea! Gabi liligi amola yagono dawa: su liligi mae fisili gaguma! Dia manohadi esoga, di da amo liligi amoga hamosu. Amabela: ? Amo liligi da di fidima: bela: ? Amoga hamosea, dia ha lai dunu da beda: ma: bela: ? Hamefa!
13 Gbogbo ìmọ̀ràn tí o ti gbà ni ó ti sọ ọ́ di akúrẹtẹ̀! Jẹ́ kí àwọn awòràwọ̀ rẹ bọ́ síwájú, àwọn awòràwọ̀ tí wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ láti oṣù dé oṣù, jẹ́ kí wọ́n gbà ọ́ lọ́wọ́ ohun tí ó ń bọ̀ wá bá ọ.
Dunu eno da dima fada: i sia: olelesa, be di da gasa hame ba: sa. Dia gasumuni ilia hou hogosu dunu da misini, di gaga: mu da defea. Ilia da gasumuni ilia hou hogole, amola mu amo ea alalo defei ba: sa. Amasea, oubi afae afae hobea dilima doaga: mu hou olelesa.
14 Lóòótọ́ wọ́n dàbí ìṣẹ́pẹ́ igi; iná ni yóò jó wọn dànù. Wọn kò kúkú lè gba ara wọn là lọ́wọ́ agbára iná náà. Kò sí èédú láti mú ara ẹnikẹ́ni gbóná níhìn-ín kò sí iná tí ènìyàn le jókòó tì.
Be ilia da bioi gisi agoane foga mini asi dagoi ba: mu. Amola, lalu da ili nemu. Ilia da ilisu gaga: mu hamedei ba: mu. Amo lalu sawa: da baligili gia: iba: le, ilia da amoga udigili dogolomu hamedei agoane ba: mu.
15 Gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe fún ọ nìyìí gbogbo èyí ní o tí ṣíṣẹ́ pẹ̀lú u rẹ̀ tí o sì ti ń rù kiri láti ìgbà èwe. Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ń lọ nínú àṣìṣe rẹ̀; kò sí ẹyọ ẹnìkan tí ó lè gbà ọ́.
Dilia da dia esalusu eso huluane ganodini, amo gasumuni ba: la: lusu dunu ilia sia: ne iasu hogosu. Be ilia da di fidimu hame dawa: Ilia da di fisili, difawane da dia logo hogoi helema: ne yolesimu. Afae da di gaga: mu hamedafa ba: mu.”

< Isaiah 47 >