< Isaiah 46 >
1 Beli tẹrí i rẹ̀ ba, Nebo bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀; àwọn ère wọn ni àwọn ẹranko rù. Àwọn ère tí wọ́n ń rù káàkiri ti di àjàgà sí wọn lọ́rùn, ẹrù fún àwọn tí àárẹ̀ mú.
Hina Gode da amane sia: sa, “Ba: bilone ilia ogogosu ‘gode’ da wadela: lesi dagoi. Musa: ilia da Ba: ile amola Nibou elama nodone sia: ne gadosu. Be wali ilia da amo liligi, dougi ilia baligi da: iya lidili legele, amo dougi da dioiwane ahoa.
2 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ wọ́n sì foríbalẹ̀ papọ̀; wọn kò lè gba ẹrù náà, àwọn pẹ̀lú ni a kó lọ ní ìgbèkùn.
Loboga hamoi ‘gode’ liligi da ili gaga: mu hamedei. Ilia eno dunu amoga lale, gaguli asi dagoi ba: sa. Amalu, Ba: bilone fi ilia ‘gode’ da bu hame ba: mu.
3 “Tẹ́tí sí mi, ìwọ ilé Jakọbu, gbogbo ẹ̀yin tí ó ṣẹ́kù nínú ilé Israẹli, ìwọ tí mo ti gbéró láti ìgbà tí o ti wà nínú oyún, tí mo sì ti ń pọ̀n láti ìgbà tí a ti bí ọ.
Ya: igobe egaga fi! Na fi dunu amo da hame bogoi esala! Na sia: nabima! Dilia lalelegeloba amola fa: no, Na da dili asigiwane ouligisu.
4 Pẹ̀lúpẹ̀lú sí àwọn arúgbó àti ewú orí yín, Èmi ni ẹni náà, Èmi ni ẹni tí yóò gbé ọ ró. Èmi ti mọ ọ́, èmi yóò sì gbé ọ; Èmi yóò dì ọ́ mú èmi ó sì gbà ọ́ sílẹ̀.
Na da dilia Gode amola Na da dili asigiwane ouligimu. Dilia da: i hamone, dialuma hinabo da ahea: iai hamosea, Na da dili ouligimu. Na da dili hahamoi amola Na da dili ouligimu. Na da dili fidimu amola gaga: mu.” Hina Gode da amane sia: sa,
5 “Ta ni ìwọ yóò fi mí wé tàbí ta ni èmi yóò bá dọ́gba? Ta ni ìwọ yóò fi ṣe àkàwé mi tí àwa yóò jọ fi ara wé ara?
“Dilia da nowa dunuma Na defema: bela: ? Dunu eno afae da Na defele hame ba: mu.
6 Ọ̀pọ̀ da wúrà sílẹ̀ nínú àpò wọn wọ́n sì wọn fàdákà lórí òsùwọ̀n; wọ́n bẹ alágbẹ̀dẹ lọ́wẹ̀ láti fi wọ́n ṣe òrìṣà, wọn sì tẹríba láti sìn ín.
Dunu da ilia muni salasu doasili, gouli sogadigisa. Ilia da silifa ea dioi defei ba: sa. Ilia gouli hahamosu dunu amo ‘gode’ liligi loboga hamoma: ne, bidi iaha. Amasea, ilia da amo ‘gode’ liligi amoma beguduli amola sia: ne gadosa.
7 Wọ́n gbé e lé èjìká wọn, wọ́n rù wọ́n, wọ́n sì gbé e sí ààyè rẹ̀ níbẹ̀ ni ó sì dúró sí. Láti ibẹ̀ náà kò le è paradà. Bí ènìyàn tilẹ̀ pariwo lé e lórí, òun kò le è dáhùn; òun kò lè gbà á nínú ìyọnu rẹ̀.
Ilia amo ogogosu ‘gode’ liligi gaguia gadole, gisawane gaguli ahoa. Ilia da ea sogebi amoga ligisili, amola amogawi amo liligi da lela. E da ea gasaga eno sogebi amoga masunu gogolei. Dunu afae da ema sia: ne gadosea, e da bu adole imunu gogolesa, amola amo dunu gaga: mu gogolesa.
8 “Rántí èyí, fi í sí ọkàn rẹ, fi sí ọkàn rẹ, ẹ̀yin ọlọ̀tẹ̀.
Dilia wadela: i hamosu dunu! Dawa: ma! Na musa: hamoi amo bu dawa: ma!
9 Rántí àwọn nǹkan àtẹ̀yìnwá, àwọn ti àtijọ́-tijọ́; Èmi ni Ọlọ́run, kò sì sí ẹlòmíràn; Èmi ni Ọlọ́run, kò sí ẹlòmíràn bí ì mi.
Hou hemonega hamoi amo bu dawa: ma! Ni fawane da Godedafa amola Na defele da ‘gode’ eno hame gala. Amo dilia dafawane dawa: le, sia: ma.
10 Mo fi òpin hàn láti ìbẹ̀rẹ̀ wá, láti àtètèkọ́ṣe, ohun tí ó sì ń bọ̀ wá. Mo wí pé, Ète mi yóò dúró, àti pé èmi yóò ṣe ohun tí ó wù mí.
Musa: hemonega, Na da hobea misunu hou huluane dawa: i dagoi. Na da musa: hemonega, amo hou da wali doaga: i dagoi, amo da doaga: mu sia: i. Na da amane sia: i, ‘Na ilegesu da hame dafamu amola Na hamomu dawa: i liligi, da didili hamoi dagoi ba: mu.’
11 Láti ìlà-oòrùn wá ni mo ti pe ẹyẹ ajẹran wá; láti ọ̀nà jíjìn réré, ọkùnrin kan tí yóò mú ète mi ṣẹ. Ohun tí mo ti sọ, òun ni èmi yóò mú ṣẹ; èyí tí mo ti gbèrò, òun ni èmi yóò ṣe.
Dunu da gusugoe amoga misa: ne Na da wele sia: nana. E da buhiba defele sa: ili, Na ilegei amo e da hamomu. Na da sia: i dagoi, amola Na sia: i huluane da hamoi dagoi ba: mu.
12 Gbọ́ tèmi, ẹ̀yin alágídí ọkàn, ìwọ tí ó jìnnà sí òdodo.
Dilia gasa fi hame nabasu dunu! Na sia: nabima! Dilia da hasalasu hou da gadenene hame agoane dawa: sa.
13 Èmi ń mú òdodo mi bọ̀ nítòsí, kò tilẹ̀ jìnnà rárá; àti ìgbàlà mi ni a kì yóò dádúró. Èmi yóò fún Sioni ní ìgbàlà ògo mi fún Israẹli.
Be Na da hamobeba: le, amo hasalasu eso da hobeadafa hame. Amo eso da gadenenewane doaga: i dagoi. Na hasalasu ba: ma: ne, dilia bagade hame ouesalumu. Na da Yelusaleme gaga: mu. Amola amogawi, Na hamobeba: le, eno fifi asi gala da Isala: ili dunu fi ilima nodone dawa: mu.”