< Isaiah 45 >
1 “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ẹni òróró rẹ̀, sí Kirusi, ọwọ́ ọ̀tún ẹni tí mo dì mú láti dojú àwọn orílẹ̀-èdè bolẹ̀ níwájú rẹ̀ àti láti gba ohun ìjà àwọn ọba lọ́wọ́ wọn, láti ṣí àwọn ìlẹ̀kùn níwájú rẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé a kì yóò ti àwọn ẹnu-ọ̀nà.
Itsho njalo iNkosi kogcotshiweyo wayo, kuKoresi, osandla sakhe sokunene ngisibambile ukuze ngehlisele phansi izizwe phambi kwakhe; ngithukulule izinkalo zamakhosi, ukuvula phambi kwakhe amasango alezivalo ezimbili, lamasango angavalwa.
2 Èmi yóò lọ síwájú rẹ, Èmi ó sì tẹ́ àwọn òkè ńlá pẹrẹsẹ Èmi yóò fọ gbogbo ẹnu-ọ̀nà idẹ èmi ó sì gé ọ̀pá irin.
Mina ngizahamba phambi kwakho, ngenze indawo ezigobileyo ziqonde, ngiphahlaze izivalo zethusi, ngiqume phakathi imigoqo yensimbi.
3 Èmi yóò sì fún ọ ní àwọn ọrọ̀ ibi òkùnkùn, ọrọ̀ tí a kó pamọ́ sí àwọn ibi tí ó fi ara sin, tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ yóò fi mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ẹni tí ó pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ.
Ngizakunika okuligugu kobumnyama, lenotho ethukuziweyo yezindawo ezisithekileyo, ukuze wazi ukuthi mina Nkosi, engikubiza ngebizo lakho, nginguNkulunkulu kaIsrayeli.
4 Nítorí Jakọbu ìránṣẹ́ mi àti Israẹli ẹni tí mo yàn, Mo pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ, mo sì gbé oyè kan kà ọ́ lórí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò gbà mí.
Ngenxa yenceku yami uJakobe, loIsrayeli umkhethwa wami, ngikubizile ngitsho ngebizo lakho, ngakunika isibongo, lanxa ungangazanga.
5 Èmi ni Olúwa, àti pé kò sí ẹlòmíràn; yàtọ̀ sí èmi kò sí ọlọ́run kan, Èmi yóò fún ọ ní okun, bí o kò tilẹ̀ tí ì gbà mí,
NgiyiNkosi, njalo kakho omunye, ngaphandle kwami kakulaNkulunkulu; ngikubhincisile lanxa ungangazanga.
6 tí o fi jẹ́ pé láti ìlà-oòrùn títí dé ibi ìwọ̀ rẹ̀ kí ènìyàn le mọ̀, kò sí ẹnìkan lẹ́yìn mi. Èmi ni Olúwa, lẹ́yìn mi kò sí ẹlòmíràn mọ́.
Ukuze bazi kusukela lapho eliphuma khona ilanga, njalo kusukela entshonalanga, ukuthi kakho omunye ngaphandle kwami; ngiyiNkosi, njalo kakho omunye.
7 Mo dá ìmọ́lẹ̀, mo sì dá òkùnkùn, Mo mú àlàáfíà wá, Mo sì dá àjálù; Èmi Olúwa ni ó ṣe nǹkan wọ̀nyí.
Ngibumba ukukhanya, ngidale umnyama; ngenza ukuthula, ngidale ububi; mina Nkosi ngenza zonke lezizinto.
8 “Ìwọ ọ̀run lókè rọ òjò òdodo sílẹ̀; jẹ́ kí àwọsánmọ̀ kí ó rọ̀ ọ́ sílẹ̀. Jẹ́ kí ilẹ̀ kí ó yanu gbagada, jẹ́ kí ìgbàlà kí ó dìde sókè, jẹ́ kí òdodo kí ó dàgbà pẹ̀lú rẹ̀; Èmi Olúwa ni ó ti dá a.
Thontisani, mazulu, kuvela phezulu, lamayezi athulule ukulunga; umhlaba kawuvuleke, njalo kuthele usindiso, njalo kakuthi ukulunga kumile kanyekanye; mina Nkosi ngikudalile.
9 “Ègbé ni fún ènìyàn tí ó ń bá Ẹlẹ́dàá rẹ̀ jà, ẹni tí òun jẹ́ àpáàdì kan láàrín àwọn àpáàdì tí ó wà lórí ilẹ̀. Ǹjẹ́ amọ̀ lè sọ fún amọ̀kòkò, pé: ‘Kí ni ohun tí ò ń ṣe?’ Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ lè sọ pé, ‘Òun kò ní ọwọ́?’ ()
Maye kuye ophikisana loMbumbi wakhe, udengezi lezindengezi zomhlabathi! Ibumba lizakutsho yini kolibumbayo ukuthi: Wenzani? kumbe: Umsebenzi wakho, kawulazandla yini?
10 Ègbé ni fún ẹni tí ó sọ fún baba rẹ̀ pé, ‘Kí ni o bí?’ tàbí sí ìyá rẹ̀, ‘Kí ni ìwọ ti bí?’
Maye kuye othi kuyise: Uzalani? kumbe kowesifazana: Ubeletheni?
11 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí, Ẹni Mímọ́ Israẹli, àti Ẹlẹ́dàá rẹ̀. Nípa ohun tí ó ń bọ̀, ǹjẹ́ o ń bi mí léèrè nípa àwọn ọmọ mi, tàbí kí o pàṣẹ fún mi nípa iṣẹ́ ọwọ́ mi bí?
Itsho njalo iNkosi, oNgcwele kaIsrayeli, loMbumbi wakhe: Buzani kimi ngezinto ezizayo, ngamadodana ami, langomsebenzi wezandla zami liyangilaya.
12 Èmi ni ẹni tí ó dá ilẹ̀ ayé tí ó sì da ọmọ ènìyàn sórí i rẹ̀. Ọwọ́ mi ni ó ti ta àwọn ọ̀run; mo sì kó àwọn àgbájọ ìràwọ̀ rẹ̀ síta.
Mina ngiwenzile umhlaba, ngadala umuntu phezu kwawo; mina, izandla zami zendlale amazulu, ngalawula amabutho awo wonke.
13 Èmi yóò gbé Kirusi sókè nínú òdodo mi. Èmi yóò mú kí gbogbo ọ̀nà rẹ̀ kí ó tọ́. Òun yóò tún ìlú mi kọ́ yóò sì tú àwọn àtìpó mi sílẹ̀, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún owó tàbí ẹ̀bùn kan, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”
Mina ngimvusile ngokulunga, njalo ngizaqondisa zonke izindlela zakhe; yena uzakwakha umuzi wami, akhulule abathunjiweyo bami, hatshi ngentengo njalo hatshi ngesivalamlomo, kutsho iNkosi yamabandla.
14 Ohun tí Olúwa wí nìyìí: “Àwọn èròjà ilẹ̀ Ejibiti àti àwọn ọjà ilẹ̀ Kuṣi, àti àwọn Sabeani— wọn yóò wá sọ́dọ̀ rẹ wọn yóò sì jẹ́ tìrẹ; wọn yóò máa wọ́ tẹ̀lé ọ lẹ́yìn, wọn yóò máa wá lọ́wọ̀ọ̀wọ́. Wọn yóò máa foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀, wọn yóò sì máa bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ pé, ‘Nítòótọ́ Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ kò sì ṣí ẹlòmíràn; kò sí ọlọ́run mìíràn.’”
Itsho njalo iNkosi: Umsebenzi weGibhithe, lokuthengiswayo kweEthiyophiya lokwamaShebha, amadoda amade, kuzadlulela kuwe, kuzakuba ngokwakho; bazakulandela, bedlule besemaketaneni, bakhothame kuwe, balabhele kuwe besithi: Isibili uNkulunkulu ukuwe, njalo kakho omunye, kakho omunye uNkulunkulu.
15 Nítòótọ́ ìwọ jẹ́ Ọlọ́run tí ó fi ara rẹ̀ pamọ́, Ìwọ Ọlọ́run àti Olùgbàlà Israẹli,
Isibili unguNkulunkulu ozifihlayo, uNkulunkulu wakoIsrayeli, uMsindisi.
16 Gbogbo àwọn tí ó ń gbẹ́ ère ni ojú yóò tì wọn yóò sì kan àbùkù; gbogbo wọn ni yóò bọ́ sínú àbùkù papọ̀.
Bazayangeka, ngitsho babe lenhloni, bonke; bazahamba belehlazo kanyekanye ababazi bezithombe.
17 Ṣùgbọ́n Israẹli ni a ó gbàlà láti ọwọ́ Olúwa pẹ̀lú ìgbàlà ayérayé; a kì yóò kàn yín lábùkù tàbí kí a dójútì yín, títí ayé àìnípẹ̀kun.
Kodwa uIsrayeli uzasindiswa eNkosini ngosindiso olulaphakade; kaliyikuyangeka, kaliyikuba lenhloni, kuze kube nini lanini.
18 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí, ẹni tí ó dá àwọn ọ̀run, Òun ni Ọlọ́run; ẹni tí ó mọ tí ó sì dá ayé, Òun ló ṣe é; Òun kò dá a láti wà lófo, ṣùgbọ́n ó ṣe é kí a lè máa gbé ibẹ̀, Òun wí pé: “Èmi ni Olúwa, kò sì ṣí ẹlòmíràn.
Ngoba itsho njalo iNkosi eyadala amazulu, yona enguNkulunkulu, eyabumba umhlaba yawenza; yona yawumisa, ingawudalelanga ize, yawubumbela ukuze kuhlalwe kuwo: NgiyiNkosi, njalo kakho omunye.
19 Èmi kò sọ̀rọ̀ níbi tí ó fi ara sin, láti ibìkan ní ilẹ̀ òkùnkùn, Èmi kò tí ì sọ fún àwọn ìran Jakọbu pé, ‘Ẹ wá mi lórí asán.’ Èmi Olúwa sọ òtítọ́, Mo sì sọ èyí tí ó tọ̀nà.
Kangikhulumelanga ekusithekeni, endaweni emnyama yomhlaba; kangitshongo kuyo inzalo kaJakobe ukuthi: Ngidingani ngeze. Mina Nkosi ngikhuluma iqiniso, ngimemezela izinto eziqotho.
20 “Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ sì wá; ẹ kórajọ, ẹ̀yin ìsáǹsá láti àwọn orílẹ̀-èdè wá. Aláìmọ̀kan ni àwọn tí ó ń ru ère igi káàkiri, tí wọ́n gbàdúrà sí àwọn òrìṣà tí kò le gba ni.
Buthanani libuye; sondelani kanyekanye, lina elaphunyuka ezizweni; abathwala izigodo zezithombe zabo ezibaziweyo kabazi, abakhuleka kunkulunkulu ongelakusindisa.
21 Jẹ́ kí a mọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀, fihàn wá, jẹ́ kí wọn jọ dámọ̀ràn papọ̀. Ta ló ti sọ èyí lọ́jọ́ tí o ti pẹ́, ta ló ti wí èyí láti àtètèkọ́ṣe? Kì í ha á ṣe Èmi, Olúwa? Àti pé kò sí Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi, Ọlọ́run olódodo àti olùgbàlà; kò sí ẹlòmíràn àfi èmi.
Tshelani, libasondeze; yebo kabacebisane kanyekanye: Ngubani owazwakalisa lokhu kwasendulo? Owakukhulumayo kusukela kulesosikhathi na? Kakusimi iNkosi yini? Njalo kakho omunye uNkulunkulu ngaphandle kwami, uNkulunkulu olungileyo loMsindisi; kakho ngaphandle kwami.
22 “Yípadà sí mi kí a sì gbà ọ́ là, ẹ̀yin ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé; nítorí Èmi ni Ọlọ́run kò sì ṣí ẹlòmíràn.
Khangelani kimi, lisindiswe, lina lonke mikhawulo yomhlaba; ngoba nginguNkulunkulu, njalo kakho omunye.
23 Nípa èmi tìkára mi ni mo ti búra, ẹnu mi ni ó ti sọ ọ́ pẹ̀lú gbogbo ipá mi, ọ̀rọ̀ náà tí a kì yóò lè parẹ́. Níwájú mi ni gbogbo orúnkún yóò wólẹ̀; nípa mi ni gbogbo ahọ́n yóò búra.
Ngizifungile mina, ilizwi liphumile emlonyeni wami ngokulunga, njalo kaliyikuphenduka, elithi: Kimi lonke idolo lizaguqa, lonke ulimi luzafunga.
24 Wọn yóò sọ ní ti èmi, ‘Nínú Olúwa nìkan ni òdodo àti agbára wà.’” Gbogbo àwọn tí ó ti bínú sí; yóò wá sọ́dọ̀ rẹ̀ a ó sì dójútì wọn.
Ngeqiniso, omunye uzakuthi: ENkosini ngilokulunga lamandla; kuyo bazakuza; kodwa bonke abayithukuthelelayo bazayangeka.
25 Ṣùgbọ́n nínú Olúwa gbogbo àwọn ìran Israẹli ni a ó rí ní òdodo, a o sì gbé wọn ga.
ENkosini yonke inzalo yakoIsrayeli izalungisiswa, izincome.