< Isaiah 45 >

1 “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ẹni òróró rẹ̀, sí Kirusi, ọwọ́ ọ̀tún ẹni tí mo dì mú láti dojú àwọn orílẹ̀-èdè bolẹ̀ níwájú rẹ̀ àti láti gba ohun ìjà àwọn ọba lọ́wọ́ wọn, láti ṣí àwọn ìlẹ̀kùn níwájú rẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé a kì yóò ti àwọn ẹnu-ọ̀nà.
“Nanku akutshoyo uThixo kogcotshiweyo wakhe, uKhurosi, engibamba isandla sakhe sokudla ukuba nginqobe izizwe eziphambi kwakhe, ngithathele amakhosi izihlangu zawo, ngivule iminyango phambi kwakhe ukuze amasango angavaleki:
2 Èmi yóò lọ síwájú rẹ, Èmi ó sì tẹ́ àwọn òkè ńlá pẹrẹsẹ Èmi yóò fọ gbogbo ẹnu-ọ̀nà idẹ èmi ó sì gé ọ̀pá irin.
Ngizahamba phambi kwakho ngenze izintaba zendlaleke. Ngizadiliza amasango ethusi, ngifohle emigoqweni yensimbi.
3 Èmi yóò sì fún ọ ní àwọn ọrọ̀ ibi òkùnkùn, ọrọ̀ tí a kó pamọ́ sí àwọn ibi tí ó fi ara sin, tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ yóò fi mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ẹni tí ó pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ.
Ngizakupha inotho yobumnyama, lenotho egcinwe ezindaweni ezifihlakeleyo ukuze wazi ukuthi mina nginguThixo, uNkulunkulu ka-Israyeli, okubiza ngebizo.
4 Nítorí Jakọbu ìránṣẹ́ mi àti Israẹli ẹni tí mo yàn, Mo pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ, mo sì gbé oyè kan kà ọ́ lórí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò gbà mí.
Ngenxa kaJakhobe inceku yami, lo-Israyeli okhethiweyo wami, ngikubiza ngebizo ngikunike ibizo lokuhlonipha, lanxa wena unganginakanga.
5 Èmi ni Olúwa, àti pé kò sí ẹlòmíràn; yàtọ̀ sí èmi kò sí ọlọ́run kan, Èmi yóò fún ọ ní okun, bí o kò tilẹ̀ tí ì gbà mí,
Mina nginguThixo, njalo kakho omunye; ngaphandle kwami akulaNkulunkulu. Ngizakuqinisa, lanxa wena unganginakanga,
6 tí o fi jẹ́ pé láti ìlà-oòrùn títí dé ibi ìwọ̀ rẹ̀ kí ènìyàn le mọ̀, kò sí ẹnìkan lẹ́yìn mi. Èmi ni Olúwa, lẹ́yìn mi kò sí ẹlòmíràn mọ́.
ukuze kuthi kusukela empumalanga kusiya entshonalanga, abantu bakwazi ukuthi kakho omunye ngaphandle kwami. Mina nginguThixo, njalo kakho omunye.
7 Mo dá ìmọ́lẹ̀, mo sì dá òkùnkùn, Mo mú àlàáfíà wá, Mo sì dá àjálù; Èmi Olúwa ni ó ṣe nǹkan wọ̀nyí.
Ngenza ukukhanya njalo ngidale umnyama, ngiletha ukuphumelela njalo ngidale incithakalo; mina Thixo ngiyazenza zonke lezizinto.
8 “Ìwọ ọ̀run lókè rọ òjò òdodo sílẹ̀; jẹ́ kí àwọsánmọ̀ kí ó rọ̀ ọ́ sílẹ̀. Jẹ́ kí ilẹ̀ kí ó yanu gbagada, jẹ́ kí ìgbàlà kí ó dìde sókè, jẹ́ kí òdodo kí ó dàgbà pẹ̀lú rẹ̀; Èmi Olúwa ni ó ti dá a.
Lina mazulu angaphezulu, nisani ukulunga; amayezi kawakuthululele phansi. Umhlaba kawuvuleke kabanzi kuhlume ukusindiswa, ukulunga akukhule lakho; mina, uThixo, ngikudalile.
9 “Ègbé ni fún ènìyàn tí ó ń bá Ẹlẹ́dàá rẹ̀ jà, ẹni tí òun jẹ́ àpáàdì kan láàrín àwọn àpáàdì tí ó wà lórí ilẹ̀. Ǹjẹ́ amọ̀ lè sọ fún amọ̀kòkò, pé: ‘Kí ni ohun tí ò ń ṣe?’ Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ lè sọ pé, ‘Òun kò ní ọwọ́?’ (questioned)
Maye kulowo ophikisa uMdali wakhe, kulowo oludengezi nje phakathi kwendengezi emhlabathini. Ibumba liyatsho na kumbumbi lithi, ‘Kuyini okubumbayo?’ Umsebenzi wakho uyatsho na uthi, ‘Kalazandla?’
10 Ègbé ni fún ẹni tí ó sọ fún baba rẹ̀ pé, ‘Kí ni o bí?’ tàbí sí ìyá rẹ̀, ‘Kí ni ìwọ ti bí?’
Maye kulowo othi kuyise, ‘Kuyini owakuzalayo?’ loba athi kunina, ‘Kuyini owakubelethayo?’
11 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí, Ẹni Mímọ́ Israẹli, àti Ẹlẹ́dàá rẹ̀. Nípa ohun tí ó ń bọ̀, ǹjẹ́ o ń bi mí léèrè nípa àwọn ọmọ mi, tàbí kí o pàṣẹ fún mi nípa iṣẹ́ ọwọ́ mi bí?
Nanku okutshiwo nguThixo, oNgcwele ka-Israyeli, loMdali wakhe uthi: Mayelana lezinto ezizayo, uyangibuza ngabatwabami na, loba uyangilawula emsebenzini engiwenzayo na?
12 Èmi ni ẹni tí ó dá ilẹ̀ ayé tí ó sì da ọmọ ènìyàn sórí i rẹ̀. Ọwọ́ mi ni ó ti ta àwọn ọ̀run; mo sì kó àwọn àgbájọ ìràwọ̀ rẹ̀ síta.
Yimi engadala umhlaba, ngenza labantu abahlala kuwo. Ezami izandla yizo ezananabula amazulu; ngahlela amaxuku ezinkanyezi zawo.
13 Èmi yóò gbé Kirusi sókè nínú òdodo mi. Èmi yóò mú kí gbogbo ọ̀nà rẹ̀ kí ó tọ́. Òun yóò tún ìlú mi kọ́ yóò sì tú àwọn àtìpó mi sílẹ̀, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún owó tàbí ẹ̀bùn kan, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”
Ngizamvusa uKhurosi ngokulunga kwami, ngenze izindlela zakhe zonke ziqonde. Uzalakha futhi idolobho lami, akhulule abami abaxotshwayo elizweni, kodwa kungekho nhlawulo kumbe umvuzo, kutsho uThixo uSomandla.”
14 Ohun tí Olúwa wí nìyìí: “Àwọn èròjà ilẹ̀ Ejibiti àti àwọn ọjà ilẹ̀ Kuṣi, àti àwọn Sabeani— wọn yóò wá sọ́dọ̀ rẹ wọn yóò sì jẹ́ tìrẹ; wọn yóò máa wọ́ tẹ̀lé ọ lẹ́yìn, wọn yóò máa wá lọ́wọ̀ọ̀wọ́. Wọn yóò máa foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀, wọn yóò sì máa bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ pé, ‘Nítòótọ́ Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ kò sì ṣí ẹlòmíràn; kò sí ọlọ́run mìíràn.’”
Nanku akutshoyo uThixo: “Izithelo zaseGibhithe lempahla ethengiswayo yaseKhushi lamaSebhina lawana amade, bazakuza kuwe babengabakho, bazakhasabula ngemva kwakho, beze kuwe bebotshwe ngamaketane. Bazakukhothamela bakuncenge besithi, ‘Ngempela uNkulunkulu ulawe, kakho omunye, kakho omunye uNkulunkulu.’”
15 Nítòótọ́ ìwọ jẹ́ Ọlọ́run tí ó fi ara rẹ̀ pamọ́, Ìwọ Ọlọ́run àti Olùgbàlà Israẹli,
Ngeqiniso unguNkulunkulu ozifihlayo, Nkulunkulu loMsindisi ka-Israyeli.
16 Gbogbo àwọn tí ó ń gbẹ́ ère ni ojú yóò tì wọn yóò sì kan àbùkù; gbogbo wọn ni yóò bọ́ sínú àbùkù papọ̀.
Bonke ababaza izithombe bazayangiswa badumazeke; bonke bazahamba beyangekile.
17 Ṣùgbọ́n Israẹli ni a ó gbàlà láti ọwọ́ Olúwa pẹ̀lú ìgbàlà ayérayé; a kì yóò kàn yín lábùkù tàbí kí a dójútì yín, títí ayé àìnípẹ̀kun.
Kodwa u-Israyeli uzasindiswa nguThixo ngensindiso engapheliyo; kaliyikuyangiswa kumbe libe lehlazo kuze kube nininini.
18 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí, ẹni tí ó dá àwọn ọ̀run, Òun ni Ọlọ́run; ẹni tí ó mọ tí ó sì dá ayé, Òun ló ṣe é; Òun kò dá a láti wà lófo, ṣùgbọ́n ó ṣe é kí a lè máa gbé ibẹ̀, Òun wí pé: “Èmi ni Olúwa, kò sì ṣí ẹlòmíràn.
Ngoba nanku okutshiwo nguThixo yena owadala amazulu, unguNkulunkulu, yena owabumba umhlaba wawenza, wawusekela; kawudalanga ukuba ungabi lalutho, kodwa wawenza ukuba kuhlalwe kuwo, uthi: “Mina nginguThixo, kakho omunye.
19 Èmi kò sọ̀rọ̀ níbi tí ó fi ara sin, láti ibìkan ní ilẹ̀ òkùnkùn, Èmi kò tí ì sọ fún àwọn ìran Jakọbu pé, ‘Ẹ wá mi lórí asán.’ Èmi Olúwa sọ òtítọ́, Mo sì sọ èyí tí ó tọ̀nà.
Angikhulumanga ensitha kwenye indawo elizweni lomnyama; angizange ngithi kuzizukulwane zikaJakhobe, ‘Ngidingani lingangitholi.’ Mina Thixo ngikhuluma iqiniso; ngitsho okuqotho.
20 “Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ sì wá; ẹ kórajọ, ẹ̀yin ìsáǹsá láti àwọn orílẹ̀-èdè wá. Aláìmọ̀kan ni àwọn tí ó ń ru ère igi káàkiri, tí wọ́n gbàdúrà sí àwọn òrìṣà tí kò le gba ni.
Qoqanani ndawonye lize kimi; buthanani lina elabaleka ezizweni. Labo abahamba bethwele izithombe zezigodo kabazi lutho; labo abakhuleka kubonkulunkulu abangeke babasize.”
21 Jẹ́ kí a mọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀, fihàn wá, jẹ́ kí wọn jọ dámọ̀ràn papọ̀. Ta ló ti sọ èyí lọ́jọ́ tí o ti pẹ́, ta ló ti wí èyí láti àtètèkọ́ṣe? Kì í ha á ṣe Èmi, Olúwa? Àti pé kò sí Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi, Ọlọ́run olódodo àti olùgbàlà; kò sí ẹlòmíràn àfi èmi.
Memezelani okufanele kube yikho, likubike, kabemukele izeluleko ndawonye. Ngubani owabika lokhu endulo, ngubani owamemezela ngakho kudala le? Kwakungayisimi mina Thixo na? Njalo kakho uNkulunkulu ngaphandle kwami, uNkulunkulu olungileyo onguMsindisi; kakho omunye, yimi kuphela.
22 “Yípadà sí mi kí a sì gbà ọ́ là, ẹ̀yin ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé; nítorí Èmi ni Ọlọ́run kò sì ṣí ẹlòmíràn.
“Phendukelani kimi lisindiswe, lonke lina mikhawulo yomhlaba; ngoba mina nginguNkulunkulu, njalo kakho omunye.
23 Nípa èmi tìkára mi ni mo ti búra, ẹnu mi ni ó ti sọ ọ́ pẹ̀lú gbogbo ipá mi, ọ̀rọ̀ náà tí a kì yóò lè parẹ́. Níwájú mi ni gbogbo orúnkún yóò wólẹ̀; nípa mi ni gbogbo ahọ́n yóò búra.
Ngifunge ngami, ngobuqotho bonke umlomo wami ukhulume ilizwi elingayikwesulwa. Amadolo wonke azaguqa phambi kwami; izindimi zonke zizafunga ngami.
24 Wọn yóò sọ ní ti èmi, ‘Nínú Olúwa nìkan ni òdodo àti agbára wà.’” Gbogbo àwọn tí ó ti bínú sí; yóò wá sọ́dọ̀ rẹ̀ a ó sì dójútì wọn.
Zizakutsho ngami zithi, ‘Ukulunga lamandla kuThixo kuphela.’” Bonke abamthukuthelelayo bazakuza kuye bayangiswe.
25 Ṣùgbọ́n nínú Olúwa gbogbo àwọn ìran Israẹli ni a ó rí ní òdodo, a o sì gbé wọn ga.
Kodwa Thixo yonke inzalo ka-Israyeli izafunyanwa ilungile, ithokoze iziqhenya ngaye.

< Isaiah 45 >