< Isaiah 45 >

1 “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ẹni òróró rẹ̀, sí Kirusi, ọwọ́ ọ̀tún ẹni tí mo dì mú láti dojú àwọn orílẹ̀-èdè bolẹ̀ níwájú rẹ̀ àti láti gba ohun ìjà àwọn ọba lọ́wọ́ wọn, láti ṣí àwọn ìlẹ̀kùn níwájú rẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé a kì yóò ti àwọn ẹnu-ọ̀nà.
Masavema frenteno azeri ruotage'ma hu'nea ne' Sairusinkura Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Nagra tamaga kaziga azante azerine'na hankavea nemisanugeno, ina kuma'mo ha'ma eme huntesniana hara hugate'nereno, kini vahera hara huzmagatereno hankavezamia eri atregahie. Nagra ranra kumatmimofo kafana anagi'na eri hagro hunentesugeno mago vahe'mo'a ana kafana eri onkigahie.
2 Èmi yóò lọ síwájú rẹ, Èmi ó sì tẹ́ àwọn òkè ńlá pẹrẹsẹ Èmi yóò fọ gbogbo ẹnu-ọ̀nà idẹ èmi ó sì gé ọ̀pá irin.
Nagra Sairusiga kavuga vugota hugante'na nevu'na, agonaramina aherava hu'na eri pehe hu'na nevu'na, bronsireti tro'ma hu'naza kuma kafantamine, ainireti'ma tro'ma hu'naza azotama kafantema rentroko'ma hunte'naza azotanena eri anafe hutregahue.
3 Èmi yóò sì fún ọ ní àwọn ọrọ̀ ibi òkùnkùn, ọrọ̀ tí a kó pamọ́ sí àwọn ibi tí ó fi ara sin, tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ yóò fi mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ẹni tí ó pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ.
Ana nehu'na zago fenoma vahe'mo'zama hanintiririma hu'nefinkama oku'ama fraki'zama ante'naza fenona eri kamigahue. Anama hanugenka nagrikura Ra Anumza mani'neno Israeli vahe'mokizmi Anumzankino, nagi aheteno huhampari nante'ne hunka, kenka antahinka hugahane.
4 Nítorí Jakọbu ìránṣẹ́ mi àti Israẹli ẹni tí mo yàn, Mo pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ, mo sì gbé oyè kan kà ọ́ lórí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò gbà mí.
Eri'za vahe'ni'a Jekopunku'ene Israeli vahe'ma nagri vahere hu'nama huhampri zamante'noa vahe'mokizmigu nentahi'na, Nagrira kenka antahinka osu'nananagi, kagrira kagia ahete'na, kavre'na kva kagia kaminoge'za husga hunegantaze.
5 Èmi ni Olúwa, àti pé kò sí ẹlòmíràn; yàtọ̀ sí èmi kò sí ọlọ́run kan, Èmi yóò fún ọ ní okun, bí o kò tilẹ̀ tí ì gbà mí,
Nagrake'za Ra Anumzana mani'noankino, magore huno nagrikna anumzana omani'ne. Nagrira kenka antahinka osu'nananagi, nagra hankavea kamigahue.
6 tí o fi jẹ́ pé láti ìlà-oòrùn títí dé ibi ìwọ̀ rẹ̀ kí ènìyàn le mọ̀, kò sí ẹnìkan lẹ́yìn mi. Èmi ni Olúwa, lẹ́yìn mi kò sí ẹlòmíràn mọ́.
E'inama hanuge'za, zage hanati kazigati'ma evuno, zage fre kazigama mani'naza vahe'mo'za, Nagrikura agrake Ra Anumzana mani'neankino, magore huno agrikna anumzana omani'ne hu'za ke'za antahi'za hugahaze.
7 Mo dá ìmọ́lẹ̀, mo sì dá òkùnkùn, Mo mú àlàáfíà wá, Mo sì dá àjálù; Èmi Olúwa ni ó ṣe nǹkan wọ̀nyí.
Nagra masa tro nehu'na, nagra haninena eri fore hu'noe. Nagra huge'za knare nomanizana nemanizage'na, Nagra huge'za vahe'mo'za knafina unefraze. Nagra Ra Anumzamo'na ama ana maka zana hugeno forera nehie.
8 “Ìwọ ọ̀run lókè rọ òjò òdodo sílẹ̀; jẹ́ kí àwọsánmọ̀ kí ó rọ̀ ọ́ sílẹ̀. Jẹ́ kí ilẹ̀ kí ó yanu gbagada, jẹ́ kí ìgbàlà kí ó dìde sókè, jẹ́ kí òdodo kí ó dàgbà pẹ̀lú rẹ̀; Èmi Olúwa ni ó ti dá a.
Anami monaramina asamigeno, ne'onse ko'mo'ma nehiaza huno fatgo avu'avazamo'a kora runo eramino, kankamuna erifore hanigeno, tagu'ma vazizamo'a hageno ome ra nehina, fatgo avu'avazamo'a magoka hageke marerigaha'e. Nagra Ra Anumzamo'na ana zana eri fore nehue.
9 “Ègbé ni fún ènìyàn tí ó ń bá Ẹlẹ́dàá rẹ̀ jà, ẹni tí òun jẹ́ àpáàdì kan láàrín àwọn àpáàdì tí ó wà lórí ilẹ̀. Ǹjẹ́ amọ̀ lè sọ fún amọ̀kòkò, pé: ‘Kí ni ohun tí ò ń ṣe?’ Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ lè sọ pé, ‘Òun kò ní ọwọ́?’ (questioned)
Hagi tro'ma hunte'nemofoma ke ha'ma renentea vahe'mo'a kva hino. Mopa kavomo'a tro'ma hunte'nemofona hafra huntegahifi? Hagi mopamo'a kavoma tro'ma nehia nekura, na'a hu'za nehane huno huge, kazana omnene huno hugahifi?
10 Ègbé ni fún ẹni tí ó sọ fún baba rẹ̀ pé, ‘Kí ni o bí?’ tàbí sí ìyá rẹ̀, ‘Kí ni ìwọ ti bí?’
Mago mofavremo'ma nefama antahigeno, mofavrea na'a nentane nehuno nereranku'ma antahigeno, mofavrea na'a kasenentanema huno'ma hania mofavremo'a hazenkefi mani'neanki kva hino.
11 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí, Ẹni Mímọ́ Israẹli, àti Ẹlẹ́dàá rẹ̀. Nípa ohun tí ó ń bọ̀, ǹjẹ́ o ń bi mí léèrè nípa àwọn ọmọ mi, tàbí kí o pàṣẹ fún mi nípa iṣẹ́ ọwọ́ mi bí?
Israeli vahetema ruotage'ma hu'neno, Israeli vahe'ma zamazeri fore'ma hu'nea Ra Anumzamo'a amanage nehie, Israeli vahete'ma henkama fore'ma hania zanku'ene nazampinti'ma tro'ma hu'noa zankura nagri nantahigeta keho.
12 Èmi ni ẹni tí ó dá ilẹ̀ ayé tí ó sì da ọmọ ènìyàn sórí i rẹ̀. Ọwọ́ mi ni ó ti ta àwọn ọ̀run; mo sì kó àwọn àgbájọ ìràwọ̀ rẹ̀ síta.
Nagra ama mopa tro hute'na ana agofetura vahe tro hu'na ante'noe. Nagra nazampinti anami monaramina tro hu'na rufanara hunentena, maka zantamine, zagene, ikane hanafitamina tro huzmante'noe.
13 Èmi yóò gbé Kirusi sókè nínú òdodo mi. Èmi yóò mú kí gbogbo ọ̀nà rẹ̀ kí ó tọ́. Òun yóò tún ìlú mi kọ́ yóò sì tú àwọn àtìpó mi sílẹ̀, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún owó tàbí ẹ̀bùn kan, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”
Nagri fatgo navu'navaza amage ante'nogu Sairusina azeri oti'noe. Ana hu'negu kama vania kana eri fatgo hu'na eri pehe hugahue. Ana hanugeno agra Nagri rankumara eri kasefa huno negino, nagri vahe'ma zamavare'za ome kinama huzmante'naza vahera zagoa e'ori ana vahera katufe zamantegahie huno Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzamo'a hu'ne.
14 Ohun tí Olúwa wí nìyìí: “Àwọn èròjà ilẹ̀ Ejibiti àti àwọn ọjà ilẹ̀ Kuṣi, àti àwọn Sabeani— wọn yóò wá sọ́dọ̀ rẹ wọn yóò sì jẹ́ tìrẹ; wọn yóò máa wọ́ tẹ̀lé ọ lẹ́yìn, wọn yóò máa wá lọ́wọ̀ọ̀wọ́. Wọn yóò máa foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀, wọn yóò sì máa bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ pé, ‘Nítòótọ́ Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ kò sì ṣí ẹlòmíràn; kò sí ọlọ́run mìíràn.’”
Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Isipi vahe'mo'zama tro hu'naza zantamimo'ene Kusi vahe'mofo zago fenomo'ene zamagima mareri'nea Seba vahe'mo'zanena tamagrike zanke segahaze. Ana nehanageta seni nofiteti kina rezmante'nesage'za tamagri tamefi ne-eza tamagiafi zamarena eme nere'za anage hugahaze, tamagerfa huno Anumzamo'a tamagrane mani'neankino Agrikna anumzana magore huno omani'ne hu'za hugahaze.
15 Nítòótọ́ ìwọ jẹ́ Ọlọ́run tí ó fi ara rẹ̀ pamọ́, Ìwọ Ọlọ́run àti Olùgbàlà Israẹli,
Israeli vahe'mokizmi Anumzamoka, vaheka'a Israeli vahera ete nezamavrana Anumza mani'nane. Ana nehunka mago'a vahetera eamara nosane.
16 Gbogbo àwọn tí ó ń gbẹ́ ère ni ojú yóò tì wọn yóò sì kan àbùkù; gbogbo wọn ni yóò bọ́ sínú àbùkù papọ̀.
Havi anumzamofo amema'ama zamazanteti'ma tro'ma nehaza vahe'mo'za tusi zamagazegu hugahaze.
17 Ṣùgbọ́n Israẹli ni a ó gbàlà láti ọwọ́ Olúwa pẹ̀lú ìgbàlà ayérayé; a kì yóò kàn yín lábùkù tàbí kí a dójútì yín, títí ayé àìnípẹ̀kun.
Hianagi Israeli vahemota fanane osu manita vanazegu, Ra Anumzamo'a tamagu vazino ete tamavrene. Ana hu'neankita vahe zamavurera tamagazegura osuta, mani vava huta vugahaze.
18 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí, ẹni tí ó dá àwọn ọ̀run, Òun ni Ọlọ́run; ẹni tí ó mọ tí ó sì dá ayé, Òun ló ṣe é; Òun kò dá a láti wà lófo, ṣùgbọ́n ó ṣe é kí a lè máa gbé ibẹ̀, Òun wí pé: “Èmi ni Olúwa, kò sì ṣí ẹlòmíràn.
Hagi monane mopanema tro huno erinte fatgo huteno, noma'arera antegeno mefatgo hunegeno amne omanenianki agigu agigu zamo mani avitesie huno tro hunte'nea Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Nagrake Ra Anumzana mani'noanki, magore huno nagrikna Anumzana omani'ne.
19 Èmi kò sọ̀rọ̀ níbi tí ó fi ara sin, láti ibìkan ní ilẹ̀ òkùnkùn, Èmi kò tí ì sọ fún àwọn ìran Jakọbu pé, ‘Ẹ wá mi lórí asán.’ Èmi Olúwa sọ òtítọ́, Mo sì sọ èyí tí ó tọ̀nà.
Nagra fraki'na hanintirima hu'nea mopafina mani'nena Jekopumpinti'ma fore hu'naza Israeli nagara oku'a nanekea tamasami'na, vahe omani kokampina nagrikura hakeho hu'na osu'noe. Nagra Ra Anumzamo'na tamage nehuankino, maka nanekema nehuana fatgo nanekege nehue.
20 “Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ sì wá; ẹ kórajọ, ẹ̀yin ìsáǹsá láti àwọn orílẹ̀-èdè wá. Aláìmọ̀kan ni àwọn tí ó ń ru ère igi káàkiri, tí wọ́n gbàdúrà sí àwọn òrìṣà tí kò le gba ni.
Tamagra ru kumapinti'ma fretama esaza vahe'mota magopi eri tru huteta erava'o hiho. Mago vahe'mo'ma havi anumzama azampi erineno zamagu'ma ovazi anumzante'ma nunamuma nehia vahera antahintahi'a omane'nea vahe mani'ne.
21 Jẹ́ kí a mọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀, fihàn wá, jẹ́ kí wọn jọ dámọ̀ràn papọ̀. Ta ló ti sọ èyí lọ́jọ́ tí o ti pẹ́, ta ló ti wí èyí láti àtètèkọ́ṣe? Kì í ha á ṣe Èmi, Olúwa? Àti pé kò sí Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi, Ọlọ́run olódodo àti olùgbàlà; kò sí ẹlòmíràn àfi èmi.
Ana vahe'mota eta eme atru magopi huteta zamatrenke'za ana havi anumzantmimo'za zamagra zamagra keaga hute'za huamara hiho, Iza menima fore'ma hania zankura kora huama hu'nea zamo eforera nehie? Nagra Ra Anumzamo'na ama anazankura huamara hutogeno eforera nehie. Nagrake fatgo navu'navara nehu'na, vaheni'a ete nezamavroa Anumza mani'noankino, magore huno Nagrikna anumzana omani'ne.
22 “Yípadà sí mi kí a sì gbà ọ́ là, ẹ̀yin ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé; nítorí Èmi ni Ọlọ́run kò sì ṣí ẹlòmíràn.
Maka ama mopafi vahe'mota Nagrite rukrahe huta enke'na tamagura vazi'nena maniho. Na'ankure Nagrake Ra Anumzana mani'noankino, magore huno nagrikna anumzana omani'ne.
23 Nípa èmi tìkára mi ni mo ti búra, ẹnu mi ni ó ti sọ ọ́ pẹ̀lú gbogbo ipá mi, ọ̀rọ̀ náà tí a kì yóò lè parẹ́. Níwájú mi ni gbogbo orúnkún yóò wólẹ̀; nípa mi ni gbogbo ahọ́n yóò búra.
Nagra Ra Anumzamo'na nagra nagifi huvempa huankino, nagipinti'ma fatgo nanekema huama'ma nehua kemo'a, amne zanknara osuno nena raga rentegahie. Ana nehina Nagri nagifi maka vahe'mo'za zamare'na eme nere'za, Nagri nagorga manigahune hu'za huvempa hugahaze.
24 Wọn yóò sọ ní ti èmi, ‘Nínú Olúwa nìkan ni òdodo àti agbára wà.’” Gbogbo àwọn tí ó ti bínú sí; yóò wá sọ́dọ̀ rẹ̀ a ó sì dójútì wọn.
Zamagra Nagrikura amanage hu'za hugahaze, Ra Anumzamofona agripinke fatgo avu'ava zane hankavenena me'ne hu'za hugahaze. Ana nehanage'za Anumzamofoma zamarimpama ahente'naza vahera esnageno zamazeri zamagaze hugahie.
25 Ṣùgbọ́n nínú Olúwa gbogbo àwọn ìran Israẹli ni a ó rí ní òdodo, a o sì gbé wọn ga.
Hianagi Jekopumpinti'ma fore'ma hu'naza Israeli vahe'mo'za, Ra Anumzamo'ma zamazeri fatgo hu'nea zanku ra zamagia erigahaze.

< Isaiah 45 >