< Isaiah 43 >

1 Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí, ohun tí Olúwa wí nìyìí, ẹni tí ó dá ọ, ìwọ Jakọbu, ẹni tí ó mọ ọ́, ìwọ Israẹli: “Má bẹ̀rù, nítorí Èmi ti dá ọ nídè; Èmi ti pè ọ́ ní orúkọ; tèmi ni ìwọ ṣe.
Isala: ili fi! Hina Gode, amo da dili hahamoi, E da amane sia: sa, “Mae beda: ma! Na da dili gaga: mu! Na da dilia dio amoga dilima wele sia: i dagoi. Dili da Na:
2 Nígbà tí ìwọ bá ń la omi kọjá, Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ; àti nígbà tí ìwọ bá ń la odò kọjá wọn kì yóò bò ọ́ mọ́lẹ̀. Nígbà tí ìwọ bá la iná kọjá, kò ní jó ọ; ahọ́n iná kò ní jó ọ lára.
Dilia da hano lugududafa amo ganodini ahoasea, Na amola ani masunu. Dilia bidi hamosu da dilima hame hasanasimu. Dilia lalu amo ganodini ahoasea, dilia nei dagoi hame ba: mu. Gasa bagade adoba: su hou da dilima doaga: sea, dilia da wadela: lesi dagoi hame ba: mu.
3 Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli Olùgbàlà rẹ; Èmi fi Ejibiti ṣe ìràpadà rẹ, Kuṣi àti Seba dípò rẹ.
Bai Na da Hina Gode, dilia Gode. Na da Isala: ili Hadigi Gode, Na da dilia gaga: su dunu esala. Na da dili bidi lama: ne, Idibidi fi fisimu. Na da dili bidi lama: ne, Sudane amola Siba sogebi fisimu.
4 Nítorí pé o ṣe iyebíye àti ọ̀wọ́n níwájú mi, àti nítorí pé mo fẹ́ràn rẹ, Èmi yóò fi ènìyàn rọ́pò fún ọ, àti ènìyàn dípò ẹ̀mí rẹ.
Na da dili gaga: ma: ne, fifi asi gala mogili fisimu. Bai dilia da Nama dogolegei fi. Dilia da Na dogolegei amola Na da dilima nodosa.
5 Má bẹ̀rù nítorí èmi wà pẹ̀lú rẹ; Èmi yóò mú àwọn ọmọ rẹ láti ìlà-oòrùn wá èmi ó sì kó ọ jọ láti ìwọ̀-oòrùn.
Mae beda: ma! Na da ani esala. Dilia fi dunu amo soge sedagaga esala mogili da gusugoe mogili da gududili, amoga Na dili buhagima: ne oule misunu
6 Èmi yóò sọ fún àríwá pé, ‘Fi wọ́n sílẹ̀!’ Àti fún gúúsù, ‘Má ṣe dá wọn dúró.’ Mú àwọn ọmọkùnrin mi láti ọ̀nà jíjìn wá àti àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin mi láti ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé—
Amola ga (north) fi ilima ilia da Na fi dunu bu misa: ne logo doasima: ne Na da sia: mu. Amola ga (south) fi ilima Na da Na fi ilia bu misunu logo amo mae gasima: ne sia: mu. Osobo bagade fifi asi gala huluane amo ganodini Na fi dunu da esala, amoga ilia bu misunu da defea.
7 ẹnikẹ́ni tí a ń pe orúkọ mi mọ́, tí mo dá fún ògo mi, tí mo mọ̀ àti tí mo ṣe.”
Ilia da Na fidafa dunu, amola ilia da Nama Hadigi ima: ne, Na da ili hahamoi dagoi.”
8 Sin àwọn tí ó ní ojú ṣùgbọ́n tí wọ́n fọ́jú jáde, tí wọ́n ní etí ṣùgbọ́n tí wọn dití.
Gode da amane sia: sa “Na fi dunu ilima fofada: musa: misa: ne sia: ma. Ilia da si gala be si dofoi. Ilia da ge gala, be ge ga: i agoane esala.
9 Gbogbo orílẹ̀-èdè kó ra wọn jọ àwọn ènìyàn sì kó ra wọn papọ̀. Ta ni nínú wọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ yìí tí ó sì kéde fún wa àwọn nǹkan ti tẹ́lẹ̀? Jẹ́ kí wọ́n mú àwọn ẹlẹ́rìí wọn wọlé wá láti fihàn pé wọ́n tọ̀nà tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn mìíràn yóò gbọ́, tí wọn yóò sọ pé, “Òtítọ́ ni.”
Fifi asi gala huluane amo fofada: musa: misa: ne sia: ma. Ilia ‘gode’ liligi afae da hobea misunu hou dawa: bela: ? Waha hamobe amo ilia da musa: ba: la: lobala: ? Amo ogogosu ‘gode’ da ilia hou amola ili sia: da moloidafa amo olelema: ne, ilia da ba: su dunu oule misunu da defea.
10 “Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí mi,” ni Olúwa wí, “Àti ìránṣẹ́ mi tí èmi ti yàn, tó bẹ́ẹ̀ tí ẹ̀yin yóò fi mọ̀ àti tí ẹ̀yin ó fi gbà mí gbọ́ tí yóò sì yé e yín pé èmi ni ẹni náà. Ṣáájú mi kò sí ọlọ́run tí a dá, tàbí a ó wa rí òmíràn lẹ́yìn mi.
Isala: ili fi dunu! Dilia da Na ba: su dunu esala. Dilia da Na hou dawa: ma: ne, amola lalegaguma: ne, Na da dili Na hawa: hamosu dunu hamoma: ne, ilegei dagoi. Nisu da Godedafa. Eno ‘gode’ da hame gala. Musa: da eno ‘gode’ hame galu amola fa: no eno ‘gode’ hamedafa ba: mu.
11 Èmi, àní Èmi, Èmi ni Olúwa, yàtọ̀ sí èmi, kò sí olùgbàlà mìíràn.
Na, Nisu da Hina Godedafa. Nisu da dili gaga: musa: dawa:
12 Èmi ti fihàn, mo gbàlà mo sì ti kéde Èmi, kì í sì í ṣe àwọn àjèjì òrìṣà láàrín yín. Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí mi,” ni Olúwa wí, “Pé Èmi ni Ọlọ́run.
Na da misunu hou amo ba: i dagoi, amola amo hou da doaga: beba: le. Na da dili fidimusa: misi. Ga fi ‘gode’ liligi da agoaiwane hame hamosu. Dilia da Na ba: su dunu esala.
13 Bẹ́ẹ̀ ni, àti láti ayérayé Èmi ni ẹni náà. Kò sí ẹnikẹ́ni tí ó lè gbà kúrò lọ́wọ́ mi. Nígbà tí mo bá ṣe nǹkan, ta ni ó lè yí i padà?”
Na da Godedafa esalu, amola Na fawane da Godedafa esalumu. Dunu da Na gasa amoga hobeamu da hamedei ba: sa. Amola dunu afae da Na hamobe amo afadenemu da hamedeidafa.”
14 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, olùràpadà rẹ, Ẹni Mímọ́ ti Israẹli: “Nítorí rẹ Èmi yóò ránṣẹ́ sí Babeli láti mú wọn sọ̀kalẹ̀ wá gẹ́gẹ́ bí ìsáǹsá, gbogbo ará Babeli, nínú ọkọ̀ ojú omi nínú èyí tí wọ́n fi ń ṣe ìgbéraga.
Isala: ili fi ilia Hadigi Gode, amo Hina Gode dilia gaga: su dunu da amane sia: sa, “Na da dili gaga: ma: ne, dadi gagui gilisisu Ba: bilone fi ilima doagala: musa: asunasimu. Na da Ba: bilone moilai bai bagade amo ea logo ga: su mugulumu. Amola Ba: bilone fi dunu ilia halasu da sinidigili, dibi fawane nabimu.
15 Èmi ni Olúwa, Ẹni Mímọ́ rẹ, Ẹlẹ́dàá Israẹli, ọba rẹ.”
Na da Hina Gode, dilia Hadigi Gode! Na da dili, Isala: ili fi, amo hahamoi, amola Na da dilima Hina bagade.”
16 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, Ẹni náà tí ó la ọ̀nà nínú Òkun, ipa ọ̀nà láàrín alagbalúgbú omi,
Hemonega Hina Gode da hano wayabo bagade amo ganodini logo ahoasu hamoi. Hano gafului ganodini, E da logo hamoi.
17 ẹni tí ó wọ́ àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin jáde, àwọn jagunjagun àti ohun ìjà papọ̀, wọ́n sì sùn síbẹ̀, láìní lè dìde mọ́, wọ́n kú pirá bí òwú-fìtílà:
E da amoga gasa bagade dadi gagui ilia sa: liode amola hosi gilisisu, amo oule misini, wadela: lesi dagoi. Ilia da bu hame wa: legadoma: ne, dafai dagoi. Ilia da gamali ha: ba: dosu defele usi dagoi ba: i.
18 “Gbàgbé àwọn ohun àtẹ̀yìnwá; má ṣe gbé nínú ohun àtijọ́.
Be Hina Gode da amane sia: sa, “Musa: hou doaga: i amoma bagadewane mae dawa: ma.
19 Wò ó, Èmi ń ṣe ohun tuntun! Nísinsin yìí, ó ti yọ sókè; àbí o kò rí i bí? Èmi ń ṣe ọ̀nà kan nínú aṣálẹ̀ àti odò nínú ilẹ̀ ṣíṣá.
Be gaheabolo hou Na da hamomu, amo noga: le ba: mu. Amo hou da wali hamonana ba: sa. Dilia da waha ba: musa: dawa: Na da iwila ganodini logo fodomu. Amogawi, Na da dilima hano imunu.
20 Àwọn ẹhànnà ẹranko bọ̀wọ̀ fún mi, àwọn ajáko àti àwọn òwìwí, nítorí pé mo pèsè omi nínú aṣálẹ̀ àti odò nínú ilẹ̀ sísá, láti fi ohun mímu fún àwọn ènìyàn mi, àyànfẹ́ mi,
Dunu amola sigua ohe fi da Nama nodomu. Soge wa: me amola “osadaligi” sio da Nama nodomu. Na da hafoga: i soge ganodini, hano yogosa: ima: ne hamone, Na fi ilegei dunu amoma hano imunu.
21 àwọn ènìyàn tí mo dá fún ara mi kí wọn kí ó lè kéde ìyìn mi.
Amo dunu Nama nodoma: ne, Na da hahamoi dagoi. Amola ilia da Nama nodone gesami hea: mu.
22 “Síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ kò tí ì ké pè mí, ìwọ Jakọbu, àárẹ̀ kò tí ì mú ọ nítorí mi ìwọ Israẹli.
Hina Gode da amane sia: sa, “Be Isala: ili dunu, dilia Nama fa: no bobogelala, hele nabi dagoi. Dilia da Nama hame nodone sia: ne gadosu.
23 Ìwọ kò tí ì mú àgùntàn wá fún mi fún ẹbọ sísun, tàbí kí o bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀lú ẹbọ rẹ. Èmi kò tí ì wàhálà rẹ pẹ̀lú ọrẹ ìyẹ̀fun tàbí kí n dààmú rẹ pẹ̀lú ìbéèrè fún tùràrí.
Dilia da sibi gobele salasu Nama ima: ne hame gaguli misi. Dilia da dilia gobele salasu amoga, Nama hame nodosu. Na da dilia da: i dioima: ne, hahawane dogolegele iasu amo dilima hame edegei. Amola dilia helema: ne, gabusiga: manoma gobele salasu hame edegei.
24 Ìwọ kò tí ì ra kalamusi olóòórùn dídùn fún mi, tàbí kí o da ọ̀rá ẹbọ rẹ bò mí. Ṣùgbọ́n ẹ ti wàhálà mi pẹ̀lú ẹ̀ṣẹ̀ yín ẹ sì ti dààmú mi pẹ̀lú àìṣedéédéé yín.
Dilia da Nama nodoma: ne, gabusiga: manoma hame bidi lai. Amola Na sadima: ne, ohe fi ea sefe amo dilia hame gaguli misi. Be dilia da Na se nabima: ne, wadela: i hou hamosu. Amola Na helema: ne, dilia da moloi hame hou hamoi dagoi.
25 “Èmi, àní Èmi, Èmi ni ẹni tí ó wẹ àwọn àìṣedéédéé rẹ nù, nítorí èmi fún ara mi, tí n kò sì rántí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ mọ́.
Be Na da Gode! Na da dilia wadela: i hou amo gogolema: ne olofomusa: dawa: Bai Na da Godedafa. Na da dilia wadela: i hou gogolele, dilima bu hame fofada: mu.
26 Bojú wo ẹ̀yìn rẹ fún mi, jẹ́ kí a jọ ṣe àríyànjiyàn ọ̀rọ̀ náà papọ̀; ro ẹjọ́ láti fihàn pé o kò lẹ́sẹ̀ lọ́rùn.
Ninia fofada: su diasuga masunu da defea. Dilia Nama diwaneya udidima! Dilia hou da moloidafa, amo ninia dawa: ma: ne, fofada: ma!
27 Baba yín àkọ́kọ́ dẹ́ṣẹ̀; àwọn agbẹnusọ yín ṣọ̀tẹ̀ sí mi.
Dilia musa: hemonega aowalali da wadela: i hou hamoi. Dilia ouligisu dunu da Nama wadela: le hamoi.
28 Nítorí náà, èmi ti sọ àwọn olórí ibi mímọ́ náà di àìmọ́, bẹ́ẹ̀ ni èmi ti fi Jakọbu fún ègún àti Israẹli fún ẹ̀gàn.
Amola dilia ouligisu dunu da Na Debolo Diasuga ledo hamosu. Amaiba: le, Na da Isala: ili fi wadela: lesi. Amola eno fi dunu da ilima gadebeba: le, Na da ili hame gaga: i.

< Isaiah 43 >