< Isaiah 42 >

1 “Ìránṣẹ́ mi nìyìí, ẹni tí mo gbéró, àyànfẹ́ mi nínú ẹni tí mo láyọ̀; Èmi yóò fi Ẹ̀mí mi sínú rẹ̀ òun yóò sì mú ìdájọ́ wá sórí àwọn orílẹ̀-èdè.
A IA hoi ka'u kauwa, ka mea a'u i malama'i, O kuu mea i waeia, a ua olioli ko'u naau ia ia; E haawi aku no au i ko'u Uhane maluna ona; A nana no e hoolaha ae ka pono no na lahuikanaka.
2 Òun kì yóò pariwo tàbí kígbe sókè, tàbí kí ó gbóhùn rẹ̀ sókè ní òpópónà.
Aole ia e kahea, aole hoi e hoowalaau aku, Aole hana aku a loheia kona leo ma ke alanui.
3 Koríko odò títẹ̀ kan ni òun kì yóò fọ́, àti òwú-fìtílà tí ń jó tan an lọ lòun kì yóò fẹ́ pa. Ní òdodo ni yóò mú ìdájọ́ wá;
Aole ia e uhai i ka ohe pepe, Aole hoi ia e kinai i ka uiki e pipi ana; A hoolaha aku oia i ka pono oiaio.
4 òun kì yóò kọsẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò ní rẹ̀wẹ̀sì títí tí yóò fi fi ìdájọ́ múlẹ̀ ní ayé. Nínú òfin rẹ̀ ni àwọn erékùṣù yóò fi ìrètí wọn sí.”
Aole ia e pio, aole hoi ia e uhaiia, A hookumu oia i ka pono ma ka honua nei: A e kakali no na mokupuni i kona kanawai.
5 Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run wí Ẹni tí ó dá àwọn ọ̀run tí ó sì tẹ́ wọ́n sóde, tí ó tẹ́ ilẹ̀ ayé àti ohun gbogbo tí ó jáde nínú wọn, Ẹni tí ó fún àwọn ènìyàn rẹ̀ ní èémí àti ẹ̀mí fún gbogbo àwọn tí ń rìn nínú rẹ̀:
Ke i mai nei ke Akua, o Iehova, penei, Ka mea nana i hana na lani, a hohola ae la ia lakou; Ka mea i hoopalahalaha ae i ka honua, a me kona mau mea ulu; Ka mea haawi i ka hanu no na kanaka maluna ona, A me ke ea hoi i ka poe e hele ana maluna ona:
6 “Èmi, Olúwa, ti pè ọ́ ní òdodo, Èmi yóò di ọwọ́ rẹ mú. Èmi yóò pa ọ́ mọ́, n ó sì ṣe ọ́ láti jẹ́ májẹ̀mú fún àwọn ènìyàn àti ìmọ́lẹ̀ fún àwọn aláìkọlà
Owau, o Iehova, ua hea aku au ia oe i mea e pono ai, A na'u no e hoopaa aku i kou lima, a e malama no hoi au ia oe, A e haawi no wau ia oe i berita no na kanaka, I malamalama hoi no ko na aina e;
7 láti la àwọn ojú tí ó fọ́, láti tú àwọn òǹdè kúrò nínú túbú àti láti tú sílẹ̀ kúrò nínú ẹ̀wọ̀n àwọn tí ó jókòó nínú òkùnkùn.
E hookaakaa i na maka o ka poe makapo, E lawe mai hoi i ka poe pio, mailoko mai o kahi paa, A me ka poe e noho ana iloko o ka pouli, mailoko mai o ka halepaahao.
8 “Èmi ni Olúwa; orúkọ mi nìyìí! Èmi kì yóò fi ògo mi fún ẹlòmíràn tàbí ìyìn mi fún ère òrìṣà.
Owau no Iehova, oia ko'u inoa; Aole au e haawi i ko'u nani ia hai, Aole hoi ko'u hanohano i na kiikalaiia.
9 Kíyèsi i, àwọn nǹkan àtijọ́ ti wáyé, àti àwọn nǹkan tuntun ni mo ti wí pé; kí wọn tó hù jáde mo ti kéde rẹ̀ fún ọ.”
Aia hoi, ua ko na mea i olelo kahiko ia, A ke hai aku nei au i na mea hou: Mamua o ko lakou hiki ana mai, ke hai aku nei au ia mau mea ia oukou.
10 Kọ orin tuntun sí Olúwa ìyìn rẹ̀ láti òpin ilẹ̀ ayé wá, ẹ̀yin tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú Òkun, àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú rẹ̀, ẹ̀yin erékùṣù, àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú wọn.
E oli aku ia Iehova i ke oli hou, I kona nani hoi mai ka welau mai o ka honua: Ka poe iho ilalo ma ka moana, a me kona mea i piha'i, O na mokupuni, a me ko lakou poe e noho ana.
11 Jẹ́ kí aginjù àti àwọn ìlú rẹ̀ kí ó gbé ohùn wọn sókè; jẹ́ kí ibùdó ti àwọn ìlú Kedari ń gbé máa yọ̀. Jẹ́ kí àwọn ènìyàn Sela kọrin fún ayọ̀; jẹ́ kí wọn pariwo láti orí òkè.
E hookiekie no ka waonahele i kona leo, A me na kulanakauhale ona, O na kauhale kahi e noho ai o Kedara; E oli hoi ka poe e noho ana ma Sela, E hooho hoi ka poe ma ka piko o na kuahiwi.
12 Jẹ́ kí wọn fi ògo fún Olúwa àti kí wọn sì kéde ìyìn rẹ̀ ní erékùṣù.
E haawi aku lakou i ka hanohano no Iehova, E hoolaha hoi i kona nani ma na aina e.
13 Olúwa yóò rìn jáde gẹ́gẹ́ bí i ọkùnrin alágbára, yóò ru owú sókè bí ológun; yóò kígbe nítòótọ́, òun yóò ké igbe ogun, òun yóò sì ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá rẹ̀.
E puka aku no o Iehova iwaho, me he koa la, E hoa no oia i ka inaina, e like me ke kanaka kaua; E hea ikaika aku no ia, a e hooho hoi; E lanakila no oia maluna o kona poe enemi.
14 “Fún ìgbà pípẹ́ ni mo ti dákẹ́ jẹ́ẹ́, mo ti wà ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, mo sì kó ara ró. Ṣùgbọ́n ní àkókò yìí, gẹ́gẹ́ bí obìnrin tí ó ń rọbí, mo sọkún, mo sì ń mí hẹlẹ hẹlẹ.
Ua noho ekemu ole au, mai kahiko loa mai; Ua noho malie au, ua uumi au i ka olelo: Aka, ano, e kahea aku no wau, e like me ka wahine hanau keiki; E luku aku no au, e hoopau pu no hoi.
15 Èmi yóò sọ òkè ńlá àti kékeré di ahoro tí n ó sì gbẹ gbogbo ewéko rẹ̀ dànù, Èmi yóò sọ àwọn odò di erékùṣù n ó sì gbẹ àwọn adágún.
E anai aku au i na kuahiwi, a me na puu, A e hoomaloo aku no au i ko lakou launahele a pau; E hoolilo wau i ko lakou muliwai i wahi maloo, A e hoomaloo no hoi au i ko lakou loko.
16 Èmi yóò tọ àwọn afọ́jú ní ọ̀nà tí wọn kò tí ì mọ̀, ní ipa ọ̀nà tí ó ṣàjèjì sí wọn ni èmi yóò tọ́ wọn lọ; Èmi yóò sọ òkùnkùn di ìmọ́lẹ̀ níwájú wọn àti ibi pálapàla ni èmi ó sọ di kíkúnná. Àwọn nǹkan tí máa ṣe nìyìí; Èmi kì yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀.
A e kai aku no au i ka poe makapo, ma ke ala a lakou i ike ole ai: E alakai no au ia lakou ma na kuamoo a lakou i ike ole ai; E hoolilo au i ka pouli i malamalama imua o lakou, A me na ala kekee i pololei. E hana no wau i keia mau mea no lakou, Aole hoi au e haalele ia lakou.
17 Ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé òrìṣà, tí wọ́n wí fún ère pé, ‘Ẹ̀yin ni Ọlọ́run wa,’ ni a ó dá padà pẹ̀lú ìtìjú.
E hoopalaimaka, a e hilahila loa hoi ka poe a pau i hilinai i na kiikalaiia, Ka poe i olelo i na kii i hooheheeia, O oukou no ko makou mau akua.
18 “Gbọ́, ìwọ adití, wò ó, ìwọ afọ́jú, o sì rí!
E hoolohe mai oukou, e na kuli, E nana hoi oukou, e ka poe makapo, i ike oukou.
19 Ta ló fọ́jú bí kò ṣe ìránṣẹ́ mi, àti odi gẹ́gẹ́ bí oníṣẹ́ tí mo rán? Ta ni ó fọ́jú gẹ́gẹ́ bí ẹni tí a fi jìnmí, ó fọ́jú gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ Olúwa?
Owai ka mea makapo, ke ole ka'u kauwa, A kuli hoi, e like me ko'u elele a'u i hoouna aku ai? Owai ka mea makapo, e like me ka mea haipule, Ka mea makapo hoi, e like me ke kauwa a Iehova?
20 Ẹ̀yin ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan, ṣùgbọ́n ẹ kò ṣe àkíyèsí; etí yín yà sílẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ kò gbọ́ nǹkan kan.”
Ua ike no oe i na mea he nui, aole nae oe i malama; Ua hakahaka na pepeiao, aole nae oia i lohe.
21 Ó dùn mọ́ Olúwa nítorí òdodo rẹ̀ láti mú òfin rẹ lágbára àti ògo.
Ua lealea no o Iehova no kona pono iho, E hoohanohano no oia i kona kanawai, a e hoonani hoi oia ia mea.
22 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn kan nìyìí tí a jà lógun tí a sì kó lẹ́rú, gbogbo wọn ni ó wà nínú ọ̀gbun, tàbí tí a fi pamọ́ sínú ẹ̀wọ̀n. Wọ́n ti di ìkógun, láìsí ẹnìkan tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀; wọ́n ti di ìkógun, láìsí ẹni tí yóò sọ pé, “Dá wọn padà.”
Aka, ua powaia keia poe kanaka, a ua haoia; Ua hoopaheleia lakou a pau maloko o na lua, Ua hunaia hoi maloko o na halepaahao; Ua lilo lakou i pio, aohe mea nana lakou e hoopakele; He mea i haoia, aohe mea i olelo mai, E hoihoi aku.
23 Ta ni nínú yín tí yóò tẹ́tí sí èyí tàbí kí ó ṣe àkíyèsí gidi ní àsìkò tí ó ń bọ̀?
Owai ka mea o oukou e haliu mai i ka pepeiao i keia? A hoolohe, a malama hoi, no ka manawa mahope?
24 Ta ni ó fi Jakọbu lélẹ̀ fún ìkógun, àti Israẹli sílẹ̀ fún onísùnmọ̀mí? Kì í ha ṣe Olúwa ni, ẹni tí àwa ti ṣẹ̀ sí? Nítorí pé wọn kò ní tẹ̀lé ọ̀nà rẹ̀; wọn kò mú òfin rẹ̀ ṣẹ.
Nawai i haawi ia Iakoba i pio, A i ka Iseraela hoi no ka poe powa? Aole anei na Iehova, ka mea a kakou i hana ino aku ai? No ka mea, aole lakou i hele i kona mau alanui, Aole lakou i hoolohe i kona kanawai.
25 Nítorí náà ni ó ṣe rọ̀jò ìbínú un rẹ̀ lé wọn lórí, rògbòdìyàn ogun. Èyí tí ó fi ahọ́n iná yí wọn po, síbẹ̀ èdè kò yé wọn; ó jó wọn run, síbẹ̀ wọn kò fi sọ́kàn wọn rárá.
Nolaila ia i ninini aku ai maluna ona, i ka wela o kona inaina, A me ka ikaika o ke kaua; A ua hoa oia ia ia i ke ahi a puni, aole nae ia i ike; Wela no oia i ke ahi, aole i manao i kona naau.

< Isaiah 42 >