< Isaiah 36 >

1 Ní ọdún kẹrìnlá ìjọba Hesekiah, Sennakeribu ọba Asiria kọlu gbogbo àwọn ìlú olódi ní ilẹ̀ Juda ó sì kó gbogbo wọn.
Ⱨǝzǝkiyaning on tɵtinqi yili xundaⱪ boldiki, Asuriyǝ padixaⱨi Sǝnnaherib Yǝⱨudaning barliⱪ ⱪǝl’ǝ-ⱪorƣanliⱪ xǝⱨǝrlirigǝ ⱨujum ⱪilip qiⱪip, ularni ixƣal ⱪildi.
2 Lẹ́yìn náà, ọba Asiria rán olórí ogun rẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ-ogun láti Lakiṣi sí ọba Hesekiah ní Jerusalẹmu. Nígbà tí ọ̀gágun náà dúró níbi ojúṣàn adágún ti apá òkè, ní ojú ọ̀nà sí pápá alágbàfọ̀,
Andin Asuriyǝ padixaⱨi «Rab-Xakǝⱨ» [degǝn sǝrdarni] qong bir ⱪoxun bilǝn Laⱪix xǝⱨiridin Yerusalemƣa ǝwǝtti. U Kir yuƣuqilarning etizining boyidiki yolda, yuⱪiri kɵlqǝkning norining bexiƣa kelip turdi.
3 Ṣebna Eliakimu ọmọ Hilkiah alábojútó ààfin, Ṣebna akọ̀wé, àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé jáde lọ pàdé rẹ̀.
Xuning bilǝn Ⱨilⱪiyaning oƣli, ordini baxⱪuridiƣan Eliakim, ordining diwanbegi bolƣan Xǝbna wǝ Asafning oƣli, orda mirzibegi bolƣan Yoaⱨlar uning yeniƣa kǝldi
4 Ọ̀gágun náà sọ fún wọn wí pé, “Ẹ sọ fún Hesekiah, “‘Èyí yìí ni ohun tí ọba ńlá, ọba Asiria sọ pé: Lórí i kí ni ìwọ gbé ìgbẹ́kẹ̀lé tìrẹ yìí lé?
wǝ Rab-Xakǝⱨ ularƣa mundaⱪ dedi: — Silǝr Ⱨǝzǝkiyaƣa: — «Uluƣ padixaⱨ, yǝni Asuriyǝ padixaⱨi sanga mundaⱪ dedi, dǝnglar: — «Sening muxu ixǝngǝn tayanqing zadi nemiti? Sǝn: (u pǝⱪǝt gǝpla, halas!) — «Urux ⱪilix tǝdbir-mǝsliⱨitimiz ⱨǝm küqimiz bar» — dǝysǝn; sǝn zadi kimgǝ tayinip manga ⱪarxi ɵktǝ ⱪopisǝn?
5 Ìwọ sọ wí pé ìwọ ní ète àti agbára ogun—ṣùgbọ́n ìwọ ń sọ ọ̀rọ̀ asán. Ta ni ìwọ gbẹ́kẹ̀lé tí ìwọ fi ṣọ̀tẹ̀ sí mi?
6 Wò ó nísinsin yìí, ìwọ gbẹ́kẹ̀lé Ejibiti ẹ̀rún igi ọ̀pá lásán tí í gún ni lọ́wọ́ tí í sì í dọ́gbẹ́ sí ni lára tí a bá gbára lé e! Bẹ́ẹ̀ ni Farao ọba Ejibiti sí àwọn tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé e.
Mana, sǝn yeriⱪi bar axu ⱪomux ⱨasa, yǝni Misirƣa tayinisǝn! Birsi uningƣa yɵlǝnsǝ, uning ⱪoliƣa sanjip kiridu; mana Misir padixaⱨi Pirǝwngǝ tayanƣanlarning ⱨǝmmisi xundaⱪ bolidu!
7 Bí o bá sì sọ fún mi pé, “Àwa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run wa,” kì í ṣe òun ni Hesekiah ti mú àwọn ibi gíga àti pẹpẹ rẹ̀ kúrò, tí ó sì wí fún Juda àti Jerusalẹmu pé, “Ẹ̀yin gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ yìí”?
Əgǝr sǝn manga: «Biz Hudayimiz bolƣan Pǝrwǝrdigarƣa tayinimiz» — desǝng, Ⱨǝzǝkiya ɵzi Yǝⱨudadikilǝrgǝ wǝ Yerusalemdikilǝrgǝ: «Silǝr pǝⱪǝt Yerusalemdiki muxu ibadǝtgaⱨ aldidila Pǝrwǝrdigarƣa ibadǝt ⱪilixinglar kerǝk» dǝp, xu [Pǝrwǝrdigarƣa] atalƣan «yuⱪiri jaylar»ni ⱨǝm ⱪurbangaⱨlarni yoⱪ ⱪiliwǝttiƣu? Ular axu Pǝrwǝrdigarning yuⱪiri jayliri ǝmǝsmidi?
8 “‘Ẹ wá nísinsin yìí, bá ọ̀gá mi pa ìmọ̀ pọ̀, ọba Asiria, èmi yóò fún ọ ní ẹgbẹ̀rún méjì ẹṣin bí ìwọ bá le è fi agẹṣin lé wọn lórí!
Əmdi hojam Asuriyǝ padixaⱨi bilǝn bir tohtamƣa kǝl: — «Əgǝr sǝndǝ atⱪa minǝligüdǝk ǝskǝrliring bolsa, mǝn sanga ikki ming atni bikarƣa berǝy!»
9 Báwo ni ẹ ṣe lè lé ẹyọ kan ṣoṣo padà nínú èyí tí ó kéré jù nínú àwọn balógun olúwa mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ gbẹ́kẹ̀lé Ejibiti fún kẹ̀kẹ́-ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin?
Sǝndǝ undaⱪlar bolmisa, hojamning ǝmǝldarlirining ǝng kiqiki bolƣan bir lǝxkǝr bexini ⱪandaⱪmu qekindürǝlǝysilǝr?! Sǝn jǝng ⱨarwiliri wǝ atlarni elix üqün Misirƣa tayinisǝn tehi!
10 Síwájú sí i, ǹjẹ́ mo wa lè wá bá ilẹ̀ yìí jà kí n sì pa á run láìsí Olúwa? Olúwa fún rara rẹ̀ ló sọ pé kí n bá orílẹ̀-èdè yìí jà kí n sì pa á run.’”
Mǝn ǝmdi muxu zeminni ⱨalak ⱪilix üqün Pǝrwǝrdigarsiz kǝldimmu? Pǝrwǝrdigar dǝrwǝⱪǝ manga: «Muxu zeminni ⱨalak ⱪilixⱪa qiⱪⱪin!» — dedi!»»
11 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu, Ṣebna àti Joah sọ fún ọ̀gágun náà pé, “Jọ̀wọ́ máa bá àwọn ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀ ní èdè Aramaiki, nítorí pé àwa gbọ́ ọ. Má ṣe bá wa sọ̀rọ̀ ní èdè Heberu ní etí àwọn ènìyàn tí ó wà lórí ògiri mọ́.”
Eliakim, Xǝbna wǝ Yoaⱨ Rab-Xakǝⱨgǝ: — «Peⱪirliriƣa aramiy tilida sɵzlisilǝ; biz buni qüxinimiz. Bizgǝ ibraniy tilida sɵzlimisilǝ, gǝpliri sepilda turƣanlarning ⱪuliⱪiƣa kirmisun!» — dedi.
12 Ṣùgbọ́n aláṣẹ dáhùn pé, “Ṣé fún ọ̀gá rẹ àti ìwọ nìkan ní ọ̀gá mi rán mi sí láti sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí kì í sì í ṣe fún àwọn ọkùnrin tí ó jókòó lórí odi ni gẹ́gẹ́ bí ìwọ, ni yóò ní láti jẹ ìgbẹ́ ará wọn kí wọ́n sì mu ìtọ̀ ará wọn?”
Biraⱪ Rab-Xakǝⱨ: — «Hojam meni muxu gǝpni hojanglarƣa wǝ silǝrgila eytixⱪa ǝwǝtkǝnmu? Muxu gǝpni silǝr bilǝn birliktǝ sepilda olturƣanlarƣa deyixkǝ ǝwǝtkǝn ǝmǝsmu? Qünki ular silǝr bilǝn birliktǝ ɵz poⱪini yegüqi ⱨǝm ɵz süydükini iqküqi bolidu!» — dedi.
13 Lẹ́yìn náà ni ọ̀gágun náà dìde tí ó sì ké síta ní èdè Heberu pé, “Ẹ gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ ọba ńlá, ọba Asiria!
Andin Rab-Xakǝⱨ ibraniy tilida yuⱪiri awaz bilǝn: — «Uluƣ padixaⱨ, yǝni Asuriyǝ padixaⱨining sɵzlirini anglap ⱪoyunglar!» — dǝp warⱪiridi.
14 Ohun tí ọba wí nìyìí, Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah tàn yín jẹ. Òun kò le è gbà yín sílẹ̀!
«Padixaⱨ mundaⱪ dǝydu: — «Ⱨǝzǝkiya silǝrni aldap ⱪoymisun! Qünki u silǝrni ⱪutⱪuzalmaydu.
15 Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah rọ̀ yín láti gbẹ́kẹ̀lé Olúwa nígbà tí ó sọ pé, ‘Olúwa yóò kúkú gbà wá; a kì yóò fi ìlú yìí lé ọba Asiria lọ́wọ́.’
Uning silǝrni: — «Pǝrwǝrdigar bizni jǝzmǝn ⱪutⱪuzidu; muxu xǝⱨǝr Asuriyǝ padixaⱨining ⱪoliƣa qüxüp kǝtmǝydu» dǝp Pǝrwǝrdigarƣa tayanduruxiƣa yol ⱪoymanglar!».
16 “Ẹ má ṣe tẹ́tí sí Hesekiah. Ohun tí ọba Asiria wí nìyìí. Ẹ fi ẹ̀bùn bá mi rẹ́, kí ẹ sì jáde tọ̀ mí wá. Lẹ́yìn náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yóò sì jẹ nínú àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni yóò sì mu omi nínú kànga rẹ̀,
Ⱨǝzǝkiyaƣa ⱪulaⱪ salmanglar; qünki Asuriyǝ padixaⱨi mundaⱪ dǝydu: — «Mǝn bilǝn sülⱨilixip, mǝn tǝrǝpkǝ ɵtünglar; xundaⱪ ⱪilsanglar ⱨǝrbiringlar ɵzünglarning üzüm baringidin ⱨǝm ɵzünglarning ǝnjür dǝrihidin mewǝ yǝysilǝr, ⱨǝrbiringlar ɵz su kɵlqikinglardin su iqisilǝr;
17 títí tí èmi yóò fi mú un yín lọ sí ilẹ̀ kan tí ó dàbí i tiyín, ilẹ̀ tí ó ní irúgbìn oníhóró àti wáìnì tuntun, ilẹ̀ tí ó ní àkàrà àti ọgbà àjàrà.
ta mǝn kelip silǝrni buƣdayliⱪ ⱨǝm xarabliⱪ bir zeminƣa, neni bar ⱨǝm üzümzarliri bar bir zeminƣa, — zemininglarƣa ohxax bir zeminƣa apirip ⱪoyƣuqǝ yǝp-iqiweringlar!
18 “Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah ṣì yín lọ́nà nígbà tí ó sọ wí pé, ‘Olúwa yóò gbà wá.’ Ǹjẹ́ ọlọ́run orílẹ̀-èdè kan ha ti gbà á kúrò lọ́wọ́ ọba Asiria bí?
Ⱨǝzǝkiyaning silǝrgǝ: — «Pǝrwǝrdigar bizni ⱪutⱪuzidu» dǝp ixǝndürüxigǝ yol ⱪoymanglar! Əl-yurtlarning ilaⱨ-butlirining biri ɵz zeminini Asuriyǝ padixaⱨining ⱪolidin ⱪutⱪuzƣanmu?
19 Níbo ni àwọn òrìṣà Hamati àti Arpadi ha wà? Níbo ni àwọn òrìṣà Sefarfaimi ha wà? Ǹjẹ́ wọn ti já Samaria gbà kúrò lọ́wọ́ mi bí?
Hamat wǝ Arpad degǝn yurtlarning ilaⱨ-butliri ⱪeni? Sǝfarwaim xǝⱨirining ilaⱨ-butliri ⱪeni? Ular Samariyǝni mening ⱪolumdin ⱪutⱪuzƣanmu?!
20 Èwo nínú àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ló ha ti dáàbò bo ilẹ̀ ẹ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi? Báwo ni Olúwa ṣe wá le gba Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ mi?”
Muxu ǝl-yurtlarning ilaⱨ-butliridin ɵz zeminini ⱪutⱪuzƣan zadi kim bar? Xundaⱪ ikǝn, Pǝrwǝrdigar Yerusalemni mening ⱪolumdin ⱪutⱪuzalamdu?»».
21 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà dákẹ́ rọ́rọ́ wọn kò sì mú èsì kankan wá, nítorí ọba ti pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe dá a lóhùn.”
Angliƣuqilar süküt ⱪilip uningƣa jawabǝn ⱨeqⱪandaⱪ bir sɵz ⱪilmidi; qünki padixaⱨning buyruⱪi xuki: — «Uningƣa jawab bǝrmǝnglar».
22 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu ọmọ Hilkiah alákòóso ààfin, Ṣebna akọ̀wé àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé àkọsílẹ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ Hesekiah pẹ̀lú aṣọ wọn ní fífàya, wọ́n sì sọ ohun tí ọ̀gágun ti wí.
Andin Ⱨilⱪiyaning oƣli, ordini baxⱪuridiƣan Eliakim, orda diwanbegi Xǝbna wǝ Asafning oƣli, orda mirzibegi Yoaⱨlar kiyim-keqǝklirini yirtixip, Ⱨǝzǝkiyaning yeniƣa kelip, Rab-Xakǝⱨning gǝplirini uningƣa uⱪturdi.

< Isaiah 36 >