< Isaiah 36 >

1 Ní ọdún kẹrìnlá ìjọba Hesekiah, Sennakeribu ọba Asiria kọlu gbogbo àwọn ìlú olódi ní ilẹ̀ Juda ó sì kó gbogbo wọn.
Mwaka wa ikũmi na ĩna wa wathani wa Mũthamaki Hezekia, Senakeribu mũthamaki wa Ashuri nĩatharĩkĩire matũũra manene mothe marĩa mairigĩirwo na thingo cia hinya ma Juda, na akĩmatunyana.
2 Lẹ́yìn náà, ọba Asiria rán olórí ogun rẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ-ogun láti Lakiṣi sí ọba Hesekiah ní Jerusalẹmu. Nígbà tí ọ̀gágun náà dúró níbi ojúṣàn adágún ti apá òkè, ní ojú ọ̀nà sí pápá alágbàfọ̀,
Ningĩ mũthamaki wa Ashuri agĩtũma mũnene wa mbũtũ ciake cia ita, kuuma Lakishi, arĩ na mbũtũ nene ya ita athiĩ kũrĩ Mũthamaki Hezekia kũu Jerusalemu. Rĩrĩa mũnene ũcio wa mbũtũ ya ita aarũgamire mũtaro-inĩ wa Karia-ka-Rũgongo, njĩra-inĩ ya gũthiĩ Mũgũnda-wa-Mũthambia-Nguo,
3 Ṣebna Eliakimu ọmọ Hilkiah alábojútó ààfin, Ṣebna akọ̀wé, àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé jáde lọ pàdé rẹ̀.
Eliakimu mũrũ wa Hilikia ũrĩa warĩ mũrori wa nyũmba ya ũthamaki, na Shebina ũrĩa mwandĩki-marũa, na Joa mũrũ wa Asafu ũrĩa mwandĩki wa maũndũ ma ihinda rĩu, makiumagara magĩthiĩ kũrĩ we.
4 Ọ̀gágun náà sọ fún wọn wí pé, “Ẹ sọ fún Hesekiah, “‘Èyí yìí ni ohun tí ọba ńlá, ọba Asiria sọ pé: Lórí i kí ni ìwọ gbé ìgbẹ́kẹ̀lé tìrẹ yìí lé?
Nake mũnene ũcio wa mbũtũ ya ita akĩmeera atĩrĩ, “Ĩrai Hezekia atĩrĩ, “‘Mũthamaki ũrĩa mũnene o we mũthamaki wa Ashuri, ekũũria atĩrĩ: Ũrutĩte ũũmĩrĩru ũcio ũrĩ naguo kũ?
5 Ìwọ sọ wí pé ìwọ ní ète àti agbára ogun—ṣùgbọ́n ìwọ ń sọ ọ̀rọ̀ asán. Ta ni ìwọ gbẹ́kẹ̀lé tí ìwọ fi ṣọ̀tẹ̀ sí mi?
Wee uugaga nĩ ũũĩ kũrũa na ũrĩ na hinya wa mbũtũ cia ita, no waragia o ciugo cia tũhũ. Nũũ ũcio wĩhokete nĩguo ũnemere?
6 Wò ó nísinsin yìí, ìwọ gbẹ́kẹ̀lé Ejibiti ẹ̀rún igi ọ̀pá lásán tí í gún ni lọ́wọ́ tí í sì í dọ́gbẹ́ sí ni lára tí a bá gbára lé e! Bẹ́ẹ̀ ni Farao ọba Ejibiti sí àwọn tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé e.
Atĩrĩrĩ, wee wĩhokete andũ a Misiri, acio mahaana ta kamũrangi koinĩkangu, karĩa gatheecaga mũndũ guoko, gakamũguraria etiirania nako! Ũguo nĩguo Firaũni mũthamaki wa Misiri ahaana kũrĩ arĩa othe mamwĩhokaga.
7 Bí o bá sì sọ fún mi pé, “Àwa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run wa,” kì í ṣe òun ni Hesekiah ti mú àwọn ibi gíga àti pẹpẹ rẹ̀ kúrò, tí ó sì wí fún Juda àti Jerusalẹmu pé, “Ẹ̀yin gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ yìí”?
O na ũngĩnjĩĩra atĩrĩ, “Ithuĩ twĩhokete Jehova Ngai witũ,” githĩ ũcio tiwe Hezekia aatharĩirie igongona na kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru, na akĩĩra andũ a Juda na a Jerusalemu atĩrĩ, “No nginya mũhooyagĩre kĩgongona-inĩ gĩkĩ”?
8 “‘Ẹ wá nísinsin yìí, bá ọ̀gá mi pa ìmọ̀ pọ̀, ọba Asiria, èmi yóò fún ọ ní ẹgbẹ̀rún méjì ẹṣin bí ìwọ bá le è fi agẹṣin lé wọn lórí!
“‘Rĩu-rĩ, ũka ũkeiguithanie na mwathi wakwa, mũthamaki wa Ashuri: Nĩngũkũhe mbarathi ngiri igĩrĩ, angĩkorwo ũrĩ na andũ a gũthiĩ macihaicĩte!
9 Báwo ni ẹ ṣe lè lé ẹyọ kan ṣoṣo padà nínú èyí tí ó kéré jù nínú àwọn balógun olúwa mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ gbẹ́kẹ̀lé Ejibiti fún kẹ̀kẹ́-ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin?
Wakĩhota atĩa gũtooria o na mũnene ũrĩa mũnini mũno thĩinĩ wa anene a mwathi wakwa, o na gũtuĩka wĩhokete ngaari cia ita na andũ arĩa mathiiaga mahaicĩte mbarathi a Misiri?
10 Síwájú sí i, ǹjẹ́ mo wa lè wá bá ilẹ̀ yìí jà kí n sì pa á run láìsí Olúwa? Olúwa fún rara rẹ̀ ló sọ pé kí n bá orílẹ̀-èdè yìí jà kí n sì pa á run.’”
Na ningĩ-rĩ, njũkĩte gũtharĩkĩra na kwananga bũrũri ũyũ iterĩĩtwo nĩ Jehova? Jehova we mwene nĩwe wanjĩĩrire njũke hũũre bũrũri ũyũ na ndĩwanange.’”
11 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu, Ṣebna àti Joah sọ fún ọ̀gágun náà pé, “Jọ̀wọ́ máa bá àwọn ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀ ní èdè Aramaiki, nítorí pé àwa gbọ́ ọ. Má ṣe bá wa sọ̀rọ̀ ní èdè Heberu ní etí àwọn ènìyàn tí ó wà lórí ògiri mọ́.”
Nao Eliakimu, na Shebina, na Joa makĩĩra mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita atĩrĩ, “Twagũthaitha arĩria ndungata ciaku na rũthiomi rwa Asuriata, tondũ nĩtũrũũĩ. Tiga gũtwarĩria na rũthiomi rwa Kĩhibirania andũ aya marĩ rũthingo-inĩ makĩiguaga.”
12 Ṣùgbọ́n aláṣẹ dáhùn pé, “Ṣé fún ọ̀gá rẹ àti ìwọ nìkan ní ọ̀gá mi rán mi sí láti sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí kì í sì í ṣe fún àwọn ọkùnrin tí ó jókòó lórí odi ni gẹ́gẹ́ bí ìwọ, ni yóò ní láti jẹ ìgbẹ́ ará wọn kí wọ́n sì mu ìtọ̀ ará wọn?”
No mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita agĩcookia atĩrĩ, “Kaĩ ndatũmirwo nĩ mwathi wakwa kũrĩ o mwathi wanyu na kũrĩ o inyuĩ, ndĩmwĩre maũndũ maya, na ti kũrĩ andũ aya maikarĩte rũthingo igũrũ, o aya makaarĩa kĩoro kĩao na manyue mathugumo mao o ene o ta ũrĩa inyuĩ mũgeeka?”
13 Lẹ́yìn náà ni ọ̀gágun náà dìde tí ó sì ké síta ní èdè Heberu pé, “Ẹ gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ ọba ńlá, ọba Asiria!
Ningĩ mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita akĩrũgama akĩanĩrĩra na Kĩhibirania, akiuga atĩrĩ, “Thikĩrĩriai ndũmĩrĩri ya mũthamaki ũrĩa mũnene, mũthamaki wa Ashuri!
14 Ohun tí ọba wí nìyìí, Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah tàn yín jẹ. Òun kò le è gbà yín sílẹ̀!
Mũthamaki ekuuga ũũ: Mũtigetĩkĩre Hezekia amũheenie. Ndangĩhota kũmũhonokia!
15 Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah rọ̀ yín láti gbẹ́kẹ̀lé Olúwa nígbà tí ó sọ pé, ‘Olúwa yóò kúkú gbà wá; a kì yóò fi ìlú yìí lé ọba Asiria lọ́wọ́.’
Mũtigetĩkĩre Hezekia amũringĩrĩrie kwĩhoka Jehova hĩndĩ ĩrĩa ekuuga atĩrĩ, ‘Ti-itherũ Jehova nĩegũtũhonokia; itũũra rĩĩrĩ inene rĩtikaaneanwo guoko-inĩ kwa mũthamaki wa Ashuri.’
16 “Ẹ má ṣe tẹ́tí sí Hesekiah. Ohun tí ọba Asiria wí nìyìí. Ẹ fi ẹ̀bùn bá mi rẹ́, kí ẹ sì jáde tọ̀ mí wá. Lẹ́yìn náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yóò sì jẹ nínú àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni yóò sì mu omi nínú kànga rẹ̀,
“Mũtigathikĩrĩrie Hezekia. Mũthamaki wa Ashuri ekuuga atĩrĩ: Rekei tũiguane na mũũke kũrĩ niĩ. Mweka ũguo, o ũmwe wanyu nĩakarĩĩaga maciaro ma mũtĩ wake wa mũthabibũ na wa mũkũyũ na anyuuage maaĩ ma gĩthima gĩake,
17 títí tí èmi yóò fi mú un yín lọ sí ilẹ̀ kan tí ó dàbí i tiyín, ilẹ̀ tí ó ní irúgbìn oníhóró àti wáìnì tuntun, ilẹ̀ tí ó ní àkàrà àti ọgbà àjàrà.
o nginya rĩrĩa ngooka ndĩmũtware bũrũri ũhaana ta wanyu, bũrũri ũrĩ ngano na ndibei ya mũhihano, bũrũri ũrĩ irio na mĩgũnda ya mĩthabibũ.
18 “Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah ṣì yín lọ́nà nígbà tí ó sọ wí pé, ‘Olúwa yóò gbà wá.’ Ǹjẹ́ ọlọ́run orílẹ̀-èdè kan ha ti gbà á kúrò lọ́wọ́ ọba Asiria bí?
“Mũtigetĩkĩre Hezekia amũhĩtithie, rĩrĩa ekuuga atĩrĩ, ‘Jehova nĩegũtũhonokia.’ Nĩ kũrĩ ngai ya rũrĩrĩ o na rũrĩkũ ĩrĩ yahonokia bũrũri wayo kuuma guoko-inĩ kwa mũthamaki wa Ashuri?
19 Níbo ni àwọn òrìṣà Hamati àti Arpadi ha wà? Níbo ni àwọn òrìṣà Sefarfaimi ha wà? Ǹjẹ́ wọn ti já Samaria gbà kúrò lọ́wọ́ mi bí?
Ngai cia Hamathu na Aripadi irĩ kũ? Ngai cia Sefarivaimu irĩ kũ? Nĩihonoketie Samaria kuuma guoko-inĩ gwakwa?
20 Èwo nínú àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ló ha ti dáàbò bo ilẹ̀ ẹ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi? Báwo ni Olúwa ṣe wá le gba Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ mi?”
Nĩ ngai ĩrĩkũ harĩ ngai ciothe cia mabũrũri macio yanahonokia bũrũri wayo kuuma kũrĩ niĩ? Gwakĩhoteka atĩa Jehova ahonokie Jerusalemu kuuma guoko-inĩ gwakwa?”
21 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà dákẹ́ rọ́rọ́ wọn kò sì mú èsì kankan wá, nítorí ọba ti pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe dá a lóhùn.”
No rĩrĩ, andũ acio magĩkira ki na matirĩ ũndũ maamũcookeirie, tondũ mũthamaki nĩamathĩte, akameera atĩrĩ, “Mũtikamũcookerie ũndũ.”
22 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu ọmọ Hilkiah alákòóso ààfin, Ṣebna akọ̀wé àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé àkọsílẹ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ Hesekiah pẹ̀lú aṣọ wọn ní fífàya, wọ́n sì sọ ohun tí ọ̀gágun ti wí.
Hĩndĩ ĩyo Eliakimu mũrũ wa Hilikia ũrĩa mũrori wa maũndũ ma nyũmba ya ũthamaki, na Shebina ũrĩa mwandĩki-marũa, na Joa mũrũ wa Asafu ũrĩa mwandĩki wa maũndũ ma ihinda rĩu, magĩthiĩ kũrĩ Hezekia, matembũrangĩte nguo ciao, makĩmwĩra ũrĩa mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita oigĩte.

< Isaiah 36 >