< Isaiah 3 >

1 Kíyèsi i, Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, fẹ́ mú ìpèsè àti ìrànlọ́wọ́ kúrò ní Jerusalẹmu àti Juda gbogbo ìpèsè oúnjẹ àti ìpèsè omi.
A IA hoi, o Iehova, ka Haku o na kaua, E lawe ana ia i na kookoo a pau, Mai ko Ierusalema, a mai ka Iuda aku, I ke kookoo a pau ma ka ai, i ke kookoo a pau ma ka wai,
2 Àwọn akíkanjú àti jagunjagun, adájọ́ àti wòlíì, aláfọ̀ṣẹ àti alàgbà,
I ka mea ikaika, a me ke kanaka koa, I ka lunakanawai, a me ke kaula. I ka mea kilokilo, a me ka mea kahiko;
3 balógun àádọ́ta àti àwọn ènìyàn, onípò gíga; olùdámọ̀ràn, oníṣọ̀nà tí ó dáńtọ́ àti ògbójú oníṣègùn.
I ka lunakanalima, a me ke kanaka koikoi, I ke kakaolelo, a me ka mea ike i na hana, I ka mea no hoi i akamai i ka hoowalewale moo.
4 “Èmi ó sọ àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin di aláṣẹ wọn, ọ̀dọ́mọdé lásán làsàn ni yóò sì máa jẹ ọba lórí i wọn.”
E haawi aku no hoi au, e noho na kamalii maluna o lakou, E noho alii no na keiki uuku maluna o lakou.
5 Àwọn ènìyàn yóò sì máa pọ́n ọmọnìkejì, wọn lójú ẹnìkan sí ẹnìkejì rẹ̀, aládùúgbò sí aládùúgbò rẹ̀. Àwọn ọ̀dọ́ yóò gbógun ti àwọn àgbàgbà, àwọn mẹ̀kúnnù yóò dìde sí ọlọ́lá.
E hookaumahaia na kanaka, kekahi e kekahi, A me ke kanaka hoi e kona hoa; A e hookiekie no ka mea opiopio maluna o ka mea kahiko, A me ka mea i hoowahawahaia maluna o ka mea hanohano.
6 Ọkùnrin kan yóò di ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin rẹ̀ mú, nínú ilé baba rẹ̀, yóò sì wí pé, “Ìwọ́ ní aṣọ, ìwọ máa ṣe olórí wa, sì mójútó àwọn ahoro wọ̀nyí!”
E lalau no ke kanaka i kona hoahanau o ka hale o kona makuakane, me ka olelo iho, Ea, he aahu no kou, e noho alii oe maluna o makou, Malalo hoi o kou lima keia pilikia.
7 Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ náà ni yóò figbe bọnu pé, “Èmi kò ní àtúnṣe kan. Èmi kò ní oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni n ó ní aṣọ nílé, ẹ má fi mí ṣe olórí àwọn ènìyàn náà.”
Ia la la, e hookiekie no kela i kona leo, me ka olelo mai, Aole au e noho hooponopono maluna o oukou, No ka mea, aohe ai ma ko'u hale, aole hoi he mea aahu; Mai hoonoho ia'u i alii maluna o kanaka;
8 Jerusalẹmu ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n Juda ń ṣubú lọ, ọ̀rọ̀ àti ìṣe wọn lòdì sí Olúwa, láti mú ojú ògo rẹ̀ bínú.
No ka mea, ua kulanalana o Ierusalema, ua haule hoi o Iuda; No ke ku e o ko lakou elelo a me ka lakou hana ia Iehova, E hoonaukiuki aku i kona mau maka hanohano.
9 Ìwò ojú wọn ń jẹ́rìí lòdì sí wọn, wọ́n ń polongo ẹ̀ṣẹ̀ wọn bí i Sodomu; wọn ò fi pamọ́! Ègbé ni fún wọn! Wọ́n ti mú ìparun wá sórí ara wọn.
O ka ike ana i ko lakou helehelena ka i hoike no lakou; Ke hai nei hoi lakou i ko lakou hewa e like me Sodoma, Aole lakou i hoole. Auwe ko lakou poe uhane! No ka mea, ua lawe mai lakou i ka hewa maluna o lakou iho.
10 Ẹ sọ fún olódodo pé yóò dára fún wọn, nítorí ní àjẹgbádùn ni wọn yóò jẹ èso iṣẹ́ ẹ wọn.
E olelo aku oukou i na mea i pono, e pomaikai lakou, No ka mea, e ai no lakou i ka hua o ka lakou hana ana.
11 Ègbé ni fún ènìyàn búburú! Ìparun wà lórí i wọn, a ó sì san èrè iṣẹ́ tí ọwọ́ wọn ti ṣe fún wọn.
Auwe hoi ka mea i hewa! e poino no ia; E haawiia'ku nana ka uku o kona mau lima.
12 Àwọn ọ̀dọ́mọdé ni o ń pọ́n àwọn ènìyàn mi lójú àwọn obìnrin ń jẹ ọba lé wọn lórí. Háà! Ènìyàn mi àwọn afinimọ̀nà yín ti ṣì yín lọ́nà, wọn sì mú yín kúrò ní ipa ọ̀nà yín.
O ko'u poe kanaka, o na kamal i ko lakou poe luna alunu, O na wahine hoi ka i noho alii maluna o lakou. E kuu poe kanaka, he poe hoolalau kou poe alakai, A ke hoopau nei lakou i ko oukou mau alanui.
13 Olúwa bọ sí ipò rẹ̀ ní ìtẹ́ ìdájọ́ Ó dìde láti dá àwọn ènìyàn lẹ́jọ́.
Ke ku nei no o Iehova e hoakaka mai, Ua ku no ia iluna e hooponopono i na kanaka.
14 Olúwa dojú ẹjọ́ kọ àwọn àgbàgbà àti àwọn olórí àwọn ènìyàn rẹ̀. “Ẹ̀yin ni ẹ ti run ọgbà àjàrà mi, ogún àwọn tálákà ń bẹ̀ nínú ilé yín.
E hele mai ana no o Iehova e hoopai, I na lunakahiko o kona poe kanaka, a me ko lakou poe alii: Ua hoopau oukou i na pawaina; Aia hoi ma ko oukou hale ka waiwai kaili wale ia o ka poe hune.
15 Kín ni èrò yín láti máa run àwọn ènìyàn mi túútúú tí ẹ sì fojú àwọn tálákà ni gbolẹ̀?” ni Olúwa wí, Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
No ke aha la oukou e hookaumaha nei i ko'u poe kanaka? A e anai i na maka o ka poe hune? Wahi a ka Haku, o Iehova o na kaua.
16 Olúwa wí pé, “Àwọn obìnrin Sioni jẹ́ agbéraga, wọn ń rìn lọ pẹ̀lú ọrùn tí ó nà tàntàn, tí wọn ń fojú pe ọkùnrin, tí wọn ń sọ̀dí bí wọ́n ti ń yan lọ pẹ̀lú ohun ọ̀ṣọ́ tí ń mì wọnjanwọnjan lọ́rùn ẹsẹ̀ wọn.
Ua olelo mai no hoi o Iehova, No ka laua haakei o na kaikamahine o Ziona, A hele me ka oeoe o na a-i, A me ka makaleho hilahila ole; He hele hooioi ko lakou hele, A kanikani na kupee o ko lakou wawae:
17 Nítorí náà Olúwa yóò mú egbò wá sórí àwọn obìnrin Sioni, Olúwa yóò sì pá wọn ní agbárí.”
E hooolohelohe no ka Haku i ka pikopoo o na kaikamahine o Ziona, E hoike no o Iehova i ko lakou wahi hilahila,
18 Ní ọjọ́ náà, Olúwa yóò já ọ̀ṣọ́ wọn gbà kúrò ti ọwọ́ àti gèlè àti ẹ̀gbà ọrùn tí ó dàbí òṣùpá
Ia la la, e lawe aku no ka Haku i ko lakou mea e nani ai, I na kupee wawae, A me na upena papale oho, A me na lei o ka a i;
19 gbogbo yẹtí, ẹ̀gbà ọwọ́ àti ìbòjú,
I na gula pepeiao, a me na kupee lima, A me na pale kalukalu;
20 gbogbo gèlè, ẹ̀gbà ọrùn, ẹsẹ̀ àti àyà, àwọn ìgò tùràrí àti òògùn,
I na papale hainaka, a me na kaula kupee wawae, I na kaei, a me na hue laau ala, A me na mea pale akua;
21 òrùka ọwọ́ àti ti imú,
I na komolima, a me na gula ihu,
22 àwọn àtàtà aṣọ, àwọ̀lékè, agbádá àti àpamọ́wọ́,
I na aahu kuai nui, a me na holoku, I na kalukalu nui, a me na hipuu kala;
23 dígí wọn, aṣọ funfun nigínnigín ìbòrí àti ìbòjú.
I na aniani nana, a me na palule, I na ribina lei o ke poo, A me na aahu nui.
24 Dípò òórùn dídùn, òórùn búburú ni yóò wá, okùn ni yóò wà dípò àmùrè, orí pípá ni yóò dípò irun ti a ṣe ní ọ̀ṣọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ ni yóò dípò aṣọ ẹ̀yẹ ìjóná dípò ẹwà.
Ma kahi i aala, e pilau ana no, Ma kahi kaei, he kaula, Ma ke oho owili e ohule ana no, Ma kahi o ka pa-u hanohano, he kaei inoino, Ma kahi maikai e paawela ana no.
25 Àwọn ọkùnrin rẹ yóò ti ipa idà ṣubú, àti àwọn jagunjagun rẹ̀ lójú ogun.
E haule no kou poe kanaka i ka pahikaua, A me kou poe koa hoi ma ke kaua.
26 Àwọn bodè Sioni yóò sọkún kíkorò, wọn ó ṣọ̀fọ̀, nítorí ó dahoro, yóò jókòó ní orí ilẹ̀.
E uwe, a e u hoi kona mau pukapa, A e noho neoneo oia ma ka lepo.

< Isaiah 3 >