< Isaiah 23 >
1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Tire. Hu, ìwọ ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi! Nítorí a ti pa Tire run láìsí ilé tàbí èbúté. Láti ilẹ̀ Saipurọsi ni ọ̀rọ̀ ti wá sọ́dọ̀ wọn.
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri nditũ ĩkoniĩ itũũra rĩa Turo: Atĩrĩrĩ, inyuĩ marikabu cia Tarishishi, ta girĩkai. Nĩgũkorwo itũũra rĩa Turo nĩrĩanange, rĩgatigwo rĩtarĩ nyũmba kana gĩcukĩro kĩa marikabu. Ũhoro ũcio nĩũmakinyĩire marĩ o kũu bũrũri wa Kitimu.
2 Dákẹ́ jẹ́ẹ́, ẹ̀yin ènìyàn erékùṣù àti ẹ̀yin oníṣòwò ti Sidoni, ẹ̀yin tí àwọn a wẹ Òkun ti sọ dọlọ́rọ̀.
Atĩrĩrĩ, inyuĩ andũ a gĩcigĩrĩra, na inyuĩ onjorithia a Sidoni, ta kirai o inyuĩ mũtongetio nĩ andũ arĩa mageragĩra iria-inĩ.
3 Láti orí àwọn omi ńlá ni irúgbìn ìyẹ̀fun ti ilẹ̀ Ṣihori ti wá; ìkórè ti odò Naili ni owóòná Tire, òun sì ti di ibùjókòó ọjà fún àwọn orílẹ̀-èdè.
Kũu maaĩ-inĩ maingĩ nĩkuo kwageragĩrio ngano ya Shihoru, namo magetha ma Nili nĩmo maarĩ uumithio wa itũũra rĩa Turo, narĩo rĩgĩtuĩka ndũnyũ ya ndũrĩrĩ.
4 Kí ojú kí ó tì ọ́, ìwọ Sidoni àti ìwọ àní ìwọ ilé ààbò ti Òkun, nítorí Òkun ti sọ̀rọ̀. “Èmi kò tí ì wà ní ipò ìrọbí tàbí ìbímọ rí Èmi kò tí ì wo àwọn ọmọkùnrin tàbí kí n tọ́ àwọn ọmọbìnrin dàgbà rí.”
Atĩrĩrĩ wee Sidoni, o nawe, kĩĩhitho kĩrũmu kĩa iria-inĩ, conokai, nĩgũkorwo iria nĩrĩarĩtie rĩkoiga atĩrĩ: “Niĩ ndirĩ ndagĩa na ruo rwa kũrũmwo, kana ngaciara; ndirĩ ndaarera aanake, kana ngarera airĩtu.”
5 Nígbà tí ọ̀rọ̀ bá dé Ejibiti, wọn yóò wà ní ìpayínkeke nípa ìròyìn láti Tire.
Hĩndĩ ĩrĩa ũhoro ũcio ũgaakinya bũrũri wa Misiri, andũ akuo nĩmakaagĩa na ruo rũnene mũno maigua ũhoro ũcio wa Turo.
6 Kọjá wá sí Tarṣiṣi; pohùnréré, ẹ̀yin ènìyàn erékùṣù.
Atĩrĩrĩ, ringai mũthiĩ mũrĩmo wa Tarishishi, ta girĩkai inyuĩ mũtũũraga kũu gĩcigĩrĩra-inĩ.
7 Ǹjẹ́ èyí náà ni ìlú àríyá yín, ògbólógbòó ìlú náà, èyí tí ẹsẹ̀ rẹ̀ ti sìn ín lọ láti lọ tẹ̀dó sí ilẹ̀ tí ó jìnnà réré.
Rĩĩrĩ nĩrĩo itũũra rĩanyu inene rĩa ikeno cia ũrĩĩu, itũũra inene rĩa kuuma tene, o tene mũno, itũũra rĩrĩa andũ aarĩo maathiĩte na magũrũ magatũũre mabũrũri ma andũ a kũraya mũno?
8 Ta ló gbèrò èyí sí Tire, ìlú aládé, àwọn oníṣòwò ẹni tí ó jẹ́ ọmọ-aládé tí àwọn oníṣòwò wọ́n jẹ́ ìlúmọ̀míká ní orílẹ̀ ayé?
Nũũ waciirĩire atĩ itũũra rĩa Turo rĩũkĩrĩrwo, o itũũra rĩu rĩheanaga tanji cia ũthamaki, o rĩo onjorithia a rĩo arĩ ariũ a athamaki, na endia a rĩo marĩ igweta thĩ yothe?
9 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti ṣètò rẹ̀, láti tẹrí ìgbéraga àti ògo rẹ ba àti láti rẹ gbogbo àwọn ọlọ́lá ilé ayé sílẹ̀.
Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩwe waciirĩire ũndũ ũcio, nĩgeetha aniine mwĩtĩĩo wa riiri wothe, na aconorithie andũ arĩa othe marĩ igweta a gũkũ thĩ.
10 Tu ilẹ̀ rẹ gẹ́gẹ́ bí i ti ipadò odò Ejibiti, ìwọ ọmọbìnrin Tarṣiṣi, nítorí ìwọ kò ní èbúté mọ́.
Atĩrĩrĩ, wee mwarĩ wa Tarishishi, thiĩ ũkarĩme bũrũri waku o ta ũrĩa kũrĩmĩtwo hũgũrũrũ-inĩ cia Rũũĩ rwa Nili, tondũ rĩu ndũrĩ na gĩcukĩro kĩa marikabu rĩngĩ.
11 Olúwa ti na ọwọ́ rẹ̀ jáde sí orí Òkun ó sì mú kí àwọn ilẹ̀ ọba wárìrì. Ó ti pa àṣẹ kan tí ó kan Kenaani pé kí a pa ilé ààbò rẹ̀ run.
Jehova nĩatambũrũkĩtie guoko gwake igũrũ rĩa iria, na agatũma mothamaki marĩo mainaine. Nĩathanĩte atĩ ciĩgitĩro iria nũmu cia Foinike cianangwo.
12 Ó wí pé, “Kò sí àríyá fún ọ mọ́, ìwọ wúńdíá ti Sidoni, tí a ti tẹ̀ mọ́lẹ̀ báyìí! “Gbéra, rékọjá lọ sí Saipurọsi, níbẹ̀ pẹ̀lú o kì yóò ní ìsinmi.”
Akoiga atĩrĩ, “Wee mwarĩ gathirange wa Sidoni ikeno ciaku cia ũrĩĩu nĩ thiru, rĩu ũrĩ mũhehenje! “Ũkĩra ũringe, ũthiĩ ũkinye Kitimu; no rĩrĩ, o na kũu ndũkoona ũhurũko.”
13 Bojú wo ilẹ̀ àwọn ará Babeli, àwọn ènìyàn tí kò jámọ́ nǹkan kan báyìí. Àwọn Asiria ti sọ ọ́ di ibùgbé àwọn ohun ẹranko aginjù; wọn ti gbé ilé ìṣọ́ ìtẹ̀gùn wọn sókè, wọ́n ti tú odi rẹ̀ sí ìhòhò wọ́n sì ti sọ ọ́ di ààtàn.
Ta rora bũrũri wa Ababuloni, andũ acio rĩu maagĩĩte kĩene! Ashuri magũtuĩte gĩikaro kĩa nyamũ cia werũ; nĩmaakire mĩthiringo mĩraihu na igũrũ ya kũrĩthiũrũrũkĩria, na magĩtiga ciĩgitĩro ciao itarĩ kĩndũ, magĩtũma bũrũri ũcio wanangĩke biũ.
14 Hu, ìwọ ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi; wọ́n ti pa odi rẹ̀ run!
Atĩrĩrĩ, inyuĩ marikabu cia Tarishishi, ta girĩkai; nĩgũkorwo gĩikaro kĩanyu nĩkĩanange.
15 Ní àkókò náà a ó gbàgbé Tire fún àádọ́rin ọdún, ọjọ́ ayé ọba kan. Ṣùgbọ́n ní òpin àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, yóò ṣẹlẹ̀ sí Tire gẹ́gẹ́ bí orin àgbèrè:
Hĩndĩ ĩyo itũũra rĩa Turo nĩrĩkariganĩra mĩaka mĩrongo mũgwanja, o ta ũrĩa matukũ ma mũthamaki ũmwe maigana. No mĩaka mĩrongo mũgwanja yathira-rĩ, Turo gũgaacooka kũhaana ta mũmaraya ũrĩa ũganagwo na rwĩmbo ta ũũ:
16 “Mú dùùrù kan, rìn kọjá láàrín ìlú, ìwọ àgbèrè tí a ti gbàgbé; lu dùùrù dáradára, kọ ọ̀pọ̀ orin, kí a lè ba à rántí rẹ.”
“Oya kĩnanda kĩa mũgeeto, ũtuĩkanie itũũra inene, wee mũmaraya ũyũ ũtũũrĩte ũriganĩire; Hũũra kĩnanda kĩa mũgeeto wega, ũine nyĩmbo nyingĩ, nĩgeetha ũririkanwo.”
17 Ní òpin àádọ́rin ọdún náà, Olúwa yóò bá Tire jà. Òun yóò sì padà sí àyálò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí panṣágà, yóò sì máa ṣe òwò rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ilẹ̀ ọba tí ó wà ní ilẹ̀ ayé.
Mĩaka mĩrongo mũgwanja yathira-rĩ, Jehova nĩagacookerera Turo. Itũũra rĩu nĩrĩgacooka wĩra-inĩ warĩo ũcio ũrehaga uumithio ta rĩkũhũũra ũmaraya, rĩonjorithanagie na mothamaki mothe ma thĩ.
18 Síbẹ̀síbẹ̀ èrè rẹ̀ àti owó iṣẹ́ rẹ̀ ni a ó yà sọ́tọ̀ fún Olúwa; a kò ní kó wọn pamọ́ tàbí kí a há wọn mọ́wọ́. Ère rẹ̀ ni a ó fi fún àwọn tí ó ń gbé níwájú Olúwa, fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ oúnjẹ àti aṣọ.
No rĩrĩ, wonjorithia warĩo na uumithio warĩo nĩikamũrĩrwo Jehova; itikaigwo igĩĩna-inĩ kana ihithwo. Uumithio warĩo ũgaatuĩka wa arĩa matũũraga marongoragia Jehova, moonage irio nyingĩ na nguo njega.