< Isaiah 21 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun. Gẹ́gẹ́ bí ìjì líle ti í jà kọjá ní gúúsù, akógunjàlú kan wá láti aginjù, láti ilẹ̀ ìpayà.
Obunnabbi obukwata ku Ddungu eririraanye ennyanja: Ng’embuyaga bwe zikunta nga ziyita mu nsi ey’obukiikaddyo, bw’atyo alumba bw’ava mu ddungu eririraanye ensi etiisa.
2 Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí ọlọ̀tẹ̀ ti tu àṣírí, fọ́lé fọ́lé ti kẹ́rù. Elamu kojú ìjà! Media ti tẹ̀gùn! Èmi yóò mú gbogbo ìpayínkeke dópin, ni ó búra.
Nfunye okwolesebwa okw’entiisa: alyamu olukwe akola omulimu gwe, n’omunyazi anyaga. Eramu, lumba! Obumeedi zingiza! Ndikomya okusinda kwonna kwe yaleeta.
3 Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí, ìrora gbá mi mú, gẹ́gẹ́ bí i ti obìnrin tí ń rọbí, mo ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nítorí ohun tí mo gbọ́, ọkàn mi pòruurù nípa ohun tí mo rí.
Omubiri gwange kyeguvudde gulumwa, n’obulumi bunkwata, ng’omukazi alumwa okuzaala; nnyiize olw’ebyo bye mpulira, bye ndaba bimazeemu amaanyi.
4 Ọkàn mí dàrú, ẹ̀rù mú jìnnìjìnnì bá mi, ìmọ́lẹ̀ tí mo ti ń fẹ́ ẹ́ rí ti wá di ìpayà fún mi.
Omutima gwange gutya, Entiisa endetera okukankana; Akasendabazaana ke nnali njayaanira, kanfukidde ekikankano.
5 Wọ́n tẹ́ tábìlì, wọ́n tẹ́ ẹní àtẹ́ẹ̀ká, wọ́n jẹ, wọ́n mu! Dìde nílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ-aládé, ẹ fi òróró kún asà yín!
Bateekateeka olujjuliro, bayalirira ebiwempe, ne balya, ne banywa! Mugolokoke mmwe abakulembeze, musiige engabo amafuta.
6 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Lọ, kí o bojúwòde kí o sì wá sọ ohun tí ó rí.
Kino Mukama ky’aŋŋamba nti, “Genda ofune omukuumi akuleetere amawulire ku ebyo by’alaba.
7 Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin, àwọn tó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí àwọn tí ó gun ìbákasẹ, jẹ́ kí ó múra sílẹ̀, àní ìmúra gidigidi.”
Bw’alaba amagaali n’ebibinja by’embalaasi, n’abeebagazi ku ndogoyi oba abeebagazi ku ŋŋamira yeekuume, era yeegendereze.”
8 Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan, “Láti ọjọ́ dé ọjọ́, olúwa mi, mo dúró lórí ilé ìṣọ́ ní ọ̀sán, a sì fi mí ìṣọ́ mi ní gbogbo òru.
Awo omukuumi n’ayogera mu ddoboozi ery’omwanguka ng’agamba nti, “Mukama wange, buli lunaku nnyimirira ku munaala, buli kiro mbeera ku mulimu gwange.
9 Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin. Ó sì mú ìdáhùn padà wá: ‘Babeli ti ṣubú, ó ti ṣubú! Gbogbo àwọn ère òrìṣà rẹ̀ ló fọ́nká sórí ilẹ̀!’”
Laba omusajja wuuno ajjira mu ggaali, ng’alina n’ekibinja ky’embalaasi. Era ayanukula bw’ati nti, ‘Babulooni kigudde, weewaawo kigudde. Ebifaananyi bya bakatonda baakyo byonna bibetenteddwa wansi ku ttaka.’”
10 Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà, mo sọ ohun tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Israẹli.
Abantu bange, abasesebbuddwa ku gguuliro, mbategeeza kyempulidde okuva eri Mukama Katonda ow’Eggye, Katonda wa Isirayiri.
11 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi. Ẹnìkan ké sí mi láti Seiri wá, “Alóre, kí ló kù nínú òru náà?”
Obunnabbi obukwata ku Duuma: Waliwo ankowoola okuva mu Seyiri ng’ayogera nti, “Omukuumi, bunaakya ddi? Omukuumi, bunaakya ddi?”
12 Alóre náà dáhùn wí pé, “Òwúrọ̀ súnmọ́ tòsí, àti òru náà pẹ̀lú. Bí ìwọ yóò bá béèrè, béèrè; kí o sì tún padà wá.”
Omukuumi ayanukula bw’ati nti, “Bulikya, era buliziba. Bw’obaako ne ky’obuuza kibuuze okomewo nate.”
13 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia. Ẹ̀yin ẹgbẹ́ èrò ti Dedani, tí ó pàgọ́ sínú igbó Arabia,
Obunnabbi obukwata ku Buwalabu: Mmwe Abadedeni abatambulira mu bibinja, abasiisira mu bisaka bya Buwalabu,
14 gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ; ẹ̀yin tí ó ń gbé Tema, gbé oúnjẹ wá fún àwọn ìsáǹsá.
muleetere abalumwa ennyonta amazzi; mmwe ababeera mu Teema, muleetere abanoonyi b’obubudamu emmere.
15 Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà, kúrò lọ́wọ́ idà tí a fàyọ, kúrò lọ́wọ́ ọrun tí a fàyọ àti kúrò nínú ìgbóná ogun.
Badduka ekitala, badduka ekitala ekisowole, badduka omutego ogunaanuddwa, badduka n’akabi k’entalo.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
Bw’ati Mukama bw’aŋŋamba nti, “Mu mwaka gumu, ng’endagaano gye bakolera omukozi bw’eba, ekitiibwa kyonna ekya Kedali kirikoma.
17 Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.
Ku b’obusaale abaliwona, ne ku basajja abalwanyi abazira ab’e Kedali, walisigalawo batono.” Mukama Katonda wa Isirayiri ayogedde.

< Isaiah 21 >