< Isaiah 21 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun. Gẹ́gẹ́ bí ìjì líle ti í jà kọjá ní gúúsù, akógunjàlú kan wá láti aginjù, láti ilẹ̀ ìpayà.
Tuipui teng kaawm e thingyeiyawn hoi kâkuen e lawk teh, akalah hoi bongparui ni a ceikhai e patetlah hothateh takitho e ramke koehoi a tho.
2 Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí ọlọ̀tẹ̀ ti tu àṣírí, fọ́lé fọ́lé ti kẹ́rù. Elamu kojú ìjà! Media ti tẹ̀gùn! Èmi yóò mú gbogbo ìpayínkeke dópin, ni ó búra.
Taki ka tho e vision hah ka hmu toe. Yuemkamcu hoeh e tami teh yuemkamcu hoeh. Ka raphoe e tami teh a raphoe. Elam khocanaw luen takhang awh. Midian khocanaw kalup awh. Hote kho kecu ka tâcawt e cingounae kaawm e pueng hah karoumsak toe.
3 Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí, ìrora gbá mi mú, gẹ́gẹ́ bí i ti obìnrin tí ń rọbí, mo ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nítorí ohun tí mo gbọ́, ọkàn mi pòruurù nípa ohun tí mo rí.
Hatdawkvah, ka keng teh patawnae hoi a kawi. Ca khenae hoi kâvan e puenghoi patawnae ni kai teh na katek. Kai teh ka thai thai hoeh nahanelah ka lung a kâsanu. Ka hmu thai hoeh nahanelah ka lung a puen.
4 Ọkàn mí dàrú, ẹ̀rù mú jìnnìjìnnì bá mi, ìmọ́lẹ̀ tí mo ti ń fẹ́ ẹ́ rí ti wá di ìpayà fún mi.
Ka lungthin a kâhei teh, ka taki dawkvah, tâlueng laihoi ka o. Dikdik ka doun e tangminlah lenghrim patenghai kaluekalap kawi lah ao toe.
5 Wọ́n tẹ́ tábìlì, wọ́n tẹ́ ẹní àtẹ́ẹ̀ká, wọ́n jẹ, wọ́n mu! Dìde nílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ-aládé, ẹ fi òróró kún asà yín!
Ahnimouh ni caboi a rakueng awh. Imrasang dawk ramveng ka ta toe. A ca awh. A nei awh. Oe kahrawikungnaw thaw awh. Bahlingnaw hah satui hluk awh.
6 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Lọ, kí o bojúwòde kí o sì wá sọ ohun tí ó rí.
Bangkongtetpawiteh, Cathut ni kai hanelah, cet haw. Ramveng ratawng sak haw. A hmu e patetlah dei sak haw.
7 Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin, àwọn tó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí àwọn tí ó gun ìbákasẹ, jẹ́ kí ó múra sílẹ̀, àní ìmúra gidigidi.”
Ahni ni, rangleng ransahu, marangransanaw, la ransahu, kalauk ransahu hah a hmu toteh, kamcengcalah a hnâpakeng vaiteh, taranhawi nalaihoi thai naseh, telah a ti.
8 Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan, “Láti ọjọ́ dé ọjọ́, olúwa mi, mo dúró lórí ilé ìṣọ́ ní ọ̀sán, a sì fi mí ìṣọ́ mi ní gbogbo òru.
Ramvengim dawk e sendek ni, Oe BAWIPA, kai teh khodai lah kanîruirui ka kangdue, karum lahai karum tuettuet ka kangdue.
9 Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin. Ó sì mú ìdáhùn padà wá: ‘Babeli ti ṣubú, ó ti ṣubú! Gbogbo àwọn ère òrìṣà rẹ̀ ló fọ́nká sórí ilẹ̀!’”
Khenhaw! Atu rangleng ransahu hoi marangransanaw teh a tho awh lahun, titeh hram laihoi a dei. Hathnukkhu, a rawp toe. Babilon kho a rawp toe. Ahnie meikaphawk cathut kaawm e pueng teh, talai dawk reppasei lah koung a rawp awh toe telah rek a dei.
10 Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà, mo sọ ohun tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Israẹli.
Ka coungroe teh, katinkaawinae hmuen koehoi ka tho e miphun, ransahu BAWIPA tie Isarelnaw e Cathut ni a dei e hah, ka thai e patetlah nangmouh hah kâhruetcuetnae na poe awh.
11 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi. Ẹnìkan ké sí mi láti Seiri wá, “Alóre, kí ló kù nínú òru náà?”
Oe ramveng, karum lah bangtelane Oe ramveng, karum lah bangtelane, telah Seir mon hoi kai hah na kaw.
12 Alóre náà dáhùn wí pé, “Òwúrọ̀ súnmọ́ tòsí, àti òru náà pẹ̀lú. Bí ìwọ yóò bá béèrè, béèrè; kí o sì tún padà wá.”
Ramveng nihai, amom a pha doeh. Karum hai a pha doeh. Pacei han ngai pawiteh pacei awh. A hnukkhu bout tho awh, telah a ti.
13 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia. Ẹ̀yin ẹgbẹ́ èrò ti Dedani, tí ó pàgọ́ sínú igbó Arabia,
Kahlawng ka cet e Dedannaw, nangmouh teh Arabia ratu dawk karum na roe awh han.
14 gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ; ẹ̀yin tí ó ń gbé Tema, gbé oúnjẹ wá fún àwọn ìsáǹsá.
Tema ram dawk kaawm e taminaw, tui kahrannaw hanelah tui sin pouh awh. Nangmouh ni ka yawng e naw hah vaiyei hoi na dawn awh toe.
15 Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà, kúrò lọ́wọ́ idà tí a fàyọ, kúrò lọ́wọ́ ọrun tí a fàyọ àti kúrò nínú ìgbóná ogun.
Bangkongtetpawiteh, nangmouh teh tahloinaw e hmalah hoi thoseh, phawk e tahloi hmalah hoi thoseh, nue tangcoung e licung pala hmalah hoi thoseh, kâtuk nah um hoi thoseh na yawng awh toe.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
BAWIPA ni kai koe hettelah a dei. Thaw tawk hanelah hlai e naw ni a parei awh e kum lahoi, kum touh thung vah, Kedar kho e bawilennae pueng teh a pout han.
17 Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.
Kacawie athakaawme Kedar capanaw, lipala ka patuem e ransanaw teh a youn awh han. Bangkongtetpawiteh, Isarelnaw e Cathut Jehovah ni hottelah yo a dei toe.

< Isaiah 21 >