< Isaiah 21 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun. Gẹ́gẹ́ bí ìjì líle ti í jà kọjá ní gúúsù, akógunjàlú kan wá láti aginjù, láti ilẹ̀ ìpayà.
Tuithim ah khosoek lamloh cangpalam bangla tinghil tih, khohmuen lamloh a rhih om neh aka pawk, tuipuei khosoek kah olrhuh.
2 Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí ọlọ̀tẹ̀ ti tu àṣírí, fọ́lé fọ́lé ti kẹ́rù. Elamu kojú ìjà! Media ti tẹ̀gùn! Èmi yóò mú gbogbo ìpayínkeke dópin, ni ó búra.
Kai taengah mangthui neh mangkhak la ha puen. Hnukpoh long tah hnukpoh coeng tih rhoelrhak long khaw rhoelrhak coeng. Elam te paan laeh, Madai te dum laeh. A hueinah boeih te ka duem sak ni.
3 Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí, ìrora gbá mi mú, gẹ́gẹ́ bí i ti obìnrin tí ń rọbí, mo ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nítorí ohun tí mo gbọ́, ọkàn mi pòruurù nípa ohun tí mo rí.
Te dongah ka cinghen he tloh kah a thueknah khaw cung coeng. Ca om vaengkah a tloh bangla kai n'tuuk. Ka yaak nen khaw ka paihaeh tih ka hmuh nawn khaw ka let coeng.
4 Ọkàn mí dàrú, ẹ̀rù mú jìnnìjìnnì bá mi, ìmọ́lẹ̀ tí mo ti ń fẹ́ ẹ́ rí ti wá di ìpayà fún mi.
Tuennah loh kai n'let sak tih ka thinko ah kho a hmang. Ka huengaihnah hlaemhmah te kai ham tah thuennah la poeh.
5 Wọ́n tẹ́ tábìlì, wọ́n tẹ́ ẹní àtẹ́ẹ̀ká, wọ́n jẹ, wọ́n mu! Dìde nílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ-aládé, ẹ fi òróró kún asà yín!
Caboei te a tloeng. Tlak te doh saeh, mangpa rhoek te ca saeh, o saeh lamtah thoo saeh. photling te koelh saeh.
6 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Lọ, kí o bojúwòde kí o sì wá sọ ohun tí ó rí.
Te dongah Boeipa loh kai taengah, “Cet laeh, rhaltawt te pai saeh lamtah a hmuh te ha puen saeh,” a ti.
7 Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin, àwọn tó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí àwọn tí ó gun ìbákasẹ, jẹ́ kí ó múra sílẹ̀, àní ìmúra gidigidi.”
Leng, marhang caem tarhoi, laak leng, kalauk leng a hmuh vaengah a hnatungnah a yet neh a hnatungnah te hnatung saeh.
8 Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan, “Láti ọjọ́ dé ọjọ́, olúwa mi, mo dúró lórí ilé ìṣọ́ ní ọ̀sán, a sì fi mí ìṣọ́ mi ní gbogbo òru.
Te phoeiah rhaltoengim kah sathueng loh, “Ka boeipa, kai khothaih puet ka pai tih ka mueitung dongah khoyin puet ka pai bal.
9 Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin. Ó sì mú ìdáhùn padà wá: ‘Babeli ti ṣubú, ó ti ṣubú! Gbogbo àwọn ère òrìṣà rẹ̀ ló fọ́nká sórí ilẹ̀!’”
Tedae marhang caem tarhoi kah hlang te leng neh ha pawk coeng he,” tila pang. Te phoeiah a doo tih, “Cungku coeng, Babylon neh a pathen mueidaep tah boeih cungku coeng tih diklai dongah phaeng rhek coeng.
10 Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà, mo sọ ohun tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Israẹli.
Ka cangtil neh ka cangtilhmuen kah ka ca taengah Israel Pathen caempuei BOEIPA taeng lamkah ka yaak te ni nangmih taengah ka puen.
11 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi. Ẹnìkan ké sí mi láti Seiri wá, “Alóre, kí ló kù nínú òru náà?”
Seir lamloh kai aka khue Dumah olrhuh loh, “Khoyin kah aka tawt khaw melae? khoyin kah aka tawt khaw balae? a ti.
12 Alóre náà dáhùn wí pé, “Òwúrọ̀ súnmọ́ tòsí, àti òru náà pẹ̀lú. Bí ìwọ yóò bá béèrè, béèrè; kí o sì tún padà wá.”
Aka tawt loh, “Mincang halo tih hlaemmuei ah na yam khaw na yam vetih na lo khaw na lo uh aih sue,” a ti.
13 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia. Ẹ̀yin ẹgbẹ́ èrò ti Dedani, tí ó pàgọ́ sínú igbó Arabia,
Arabia ham olrhuh, Arabia duup ah naka rhaeh Dedanim lambong rhoek.
14 gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ; ẹ̀yin tí ó ń gbé Tema, gbé oúnjẹ wá fún àwọn ìsáǹsá.
Tuihalh doe ham te Tema kho kah khosa rhoek loh tui hang khuen saeh, amah buh neh aka doe rhoek khaw yong coeng.
15 Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà, kúrò lọ́wọ́ idà tí a fàyọ, kúrò lọ́wọ́ ọrun tí a fàyọ àti kúrò nínú ìgbóná ogun.
cunghang taeng lamloh, cunghang aka bong mikhmuh lamloh, lii aka phu kah mikhmuh lamloh, caemtloek hnorhih kah mikhmuh lamloh yong uh.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
Te dongah Boeipa loh kai taengah, “Kum khat khuiah kutloh kum kah bangla om vetih Kedar kah a thangpomnah khaw boeih bawt ni.
17 Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.
Kedar ca khuikah hlangrhalh lii pom te amah tarhing ah aka sueng khaw Israel Pathen Yahovah loh a thui coeng dongah polpai uh ni,” a ti.

< Isaiah 21 >