< Isaiah 20 >
1 Ní ọdún tí olórí ogun, tí Sagoni ọba Asiria rán an, wá sí Aṣdodu, ó kọlù ú ó sì kó o—
Ын анул кынд а венит Тартан ла Асдод, тримис де Саргон, ымпэратул Асирией, сэ батэ Асдодул ши л-а луат,
2 ní àkókò náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa ti ẹnu Isaiah ọmọ Amosi jáde. Ó sọ fún un pé, “Mú aṣọ ọ̀fọ̀ kúrò ní ara rẹ kí o sì bọ́ sálúbàtà kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ.” Ó sì ṣe bẹ́ẹ̀, ó ń lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà.
ын время ачея, Домнул а ворбит луй Исая, фиул луй Амоц ши й-а зис: „Ду-те, дезлягэ-ць сакул де пе коапсе ши скоате-ць ынкэлцэминтя дин пичоаре!” Ел а фэкут аша, а умблат гол ши дескулц.
3 Lẹ́yìn náà ni Olúwa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ mi Isaiah ti lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà fún ọdún mẹ́ta, gẹ́gẹ́ bí àmì àti àpẹẹrẹ sí Ejibiti àti Kuṣi,
Ши Домнул а зис: „Дупэ кум робул меу Исая умблэ гол ши дескулц трей ань де зиле, ка семн ши ынштиинцаре пентру Еӂипт ши пентру Етиопия,
4 bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọba Asiria yóò kó àwọn ìgbèkùn Ejibiti lọ ní ìhòhò àti láì wọ bàtà pẹ̀lú àwọn àtìpó Kuṣi, ọ̀dọ́ àti àgbà, pẹ̀lú ìbàdí ìhòhò—bí àbùkù Ejibiti.
тот аша ши ымпэратул Асирией ва луа дин Еӂипт ши дин Етиопия приншь де рэзбой ши сургюниць, тинерь ши бэтрынь, гой ши дескулць ши ку спинаря дескоперитэ, спре рушиня Еӂиптулуй.
5 Gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Kuṣi tí wọ́n sì ń fi Ejibiti yangàn ni ẹ̀rù yóò dé bá tí a ó sì dójútì wọ́n.
Атунч се вор ынгрози ши се вор рушина чей че ышь пусесерэ ынкредеря ын Етиопия ши се фэляу ку Еӂиптул.
6 Ní ọjọ́ náà àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ní etí Òkun yóò wí pé, ‘Wo ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí a ti gbẹ́kẹ̀lé, àwọn tí a sá tọ̀ lọ fún ìrànlọ́wọ́ àti ìtúsílẹ̀ láti ọwọ́ ọba Asiria! Báwo ni a ó ṣe sálà?’”
Ши локуиторий де пе цэрмул ачеста вор зиче ын зиуа ачея: ‘Ятэ че а ажунс ынкредеря ноастрэ пе каре не бизуисерэм ка сэ фим ажутаць ши сэ фим избэвиць де ымпэратул Асирией! Кум вом скэпа акум?’”