< Isaiah 20 >

1 Ní ọdún tí olórí ogun, tí Sagoni ọba Asiria rán an, wá sí Aṣdodu, ó kọlù ú ó sì kó o—
Iti tawen nga immay ni Tartan idiay Asdod, idi imbaon isuna ni Sargon nga ari ti Asiria, nakiranget isuna iti Asdod ket sinakupna daytoy.
2 ní àkókò náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa ti ẹnu Isaiah ọmọ Amosi jáde. Ó sọ fún un pé, “Mú aṣọ ọ̀fọ̀ kúrò ní ara rẹ kí o sì bọ́ sálúbàtà kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ.” Ó sì ṣe bẹ́ẹ̀, ó ń lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà.
Iti dayta a tiempo, nagsao ni Yahweh babaen kenni Isaias a putot ni Amos a kinunana, “Mapanka ket ikkatem ti nakersang a lupot iti siketmo ken ikkatem dagita sandaliasmo.” Kasta ngarud ti inaramidna, nagnagna a lamolamo ken sakasaka.
3 Lẹ́yìn náà ni Olúwa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ mi Isaiah ti lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà fún ọdún mẹ́ta, gẹ́gẹ́ bí àmì àti àpẹẹrẹ sí Ejibiti àti Kuṣi,
Kinuna ni Yahweh, “Kas iti adipenko a ni Isaias a nagna a lamolamo ken sakasaka iti las-ud ti tallo a tawen, pagilasinan ken ballaag daytoy maipapan iti Egipto ken maipapan ti Etiopia-
4 bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọba Asiria yóò kó àwọn ìgbèkùn Ejibiti lọ ní ìhòhò àti láì wọ bàtà pẹ̀lú àwọn àtìpó Kuṣi, ọ̀dọ́ àti àgbà, pẹ̀lú ìbàdí ìhòhò—bí àbùkù Ejibiti.
iti kastoy a wagas nga ipanawto ti ari ti Asiria dagiti natiliw a kas balud a taga-Egipto ken dagiti naipanaw a kas balud a taga-Etiopia, ubing ken nataengan, lamolamo ken sakasaka ken saan a naabbongan dagiti patongda, a pakaibabainan ti Egipto.
5 Gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Kuṣi tí wọ́n sì ń fi Ejibiti yangàn ni ẹ̀rù yóò dé bá tí a ó sì dójútì wọ́n.
Maupay ken maibabaindanto, gapu ta ti Etiopia ti namnamada ken ti Egipto ti dayagda.
6 Ní ọjọ́ náà àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ní etí Òkun yóò wí pé, ‘Wo ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí a ti gbẹ́kẹ̀lé, àwọn tí a sá tọ̀ lọ fún ìrànlọ́wọ́ àti ìtúsílẹ̀ láti ọwọ́ ọba Asiria! Báwo ni a ó ṣe sálà?’”
Dagiti agnanaed kadagitoy nga igid ti baybay ket ibagadanto iti dayta nga aldaw, 'Pudno, daytoy ti nagtaudan ti namnamatayo, a nagkamangantayo tapno maispaltayo manipud iti Ari ti Asiria, ket ita, kasanotayo ngay a makalibas?’”

< Isaiah 20 >