< Isaiah 20 >

1 Ní ọdún tí olórí ogun, tí Sagoni ọba Asiria rán an, wá sí Aṣdodu, ó kọlù ú ó sì kó o—
Atĩrĩrĩ, mwaka ũcio mũnene wa anene a ita rĩa Ashuri aakinyire Ashidodi atũmĩtwo nĩ Sarigoni mũthamaki wa Ashuri, aakinya kuo, na aarĩtharĩkĩra na aarĩtunyana-rĩ,
2 ní àkókò náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa ti ẹnu Isaiah ọmọ Amosi jáde. Ó sọ fún un pé, “Mú aṣọ ọ̀fọ̀ kúrò ní ara rẹ kí o sì bọ́ sálúbàtà kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ.” Ó sì ṣe bẹ́ẹ̀, ó ń lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà.
hĩndĩ ĩyo nĩguo Jehova aaririe na kanua ka Isaia mũrũ wa Amozu. Akĩmwĩra atĩrĩ, “Ruta nguo ĩyo ya ikũnia wĩhumbĩte, na ũrute iraatũ ciaku magũrũ.” Nake agĩĩka o ro ũguo, agĩthiĩ njaga na arĩ magũrũ matheri.
3 Lẹ́yìn náà ni Olúwa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ mi Isaiah ti lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà fún ọdún mẹ́ta, gẹ́gẹ́ bí àmì àti àpẹẹrẹ sí Ejibiti àti Kuṣi,
Ningĩ Jehova akiuga atĩrĩ, “O ta ũguo ndungata yakwa Isaia athiĩte njaga na arĩ magũrũ matheri mĩaka ĩtatũ, arĩ rũũri na kĩmenyithia kĩa maũndũ mooru marĩa magaakora bũrũri wa Misiri na wa Kushi-rĩ,
4 bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọba Asiria yóò kó àwọn ìgbèkùn Ejibiti lọ ní ìhòhò àti láì wọ bàtà pẹ̀lú àwọn àtìpó Kuṣi, ọ̀dọ́ àti àgbà, pẹ̀lú ìbàdí ìhòhò—bí àbùkù Ejibiti.
ũguo noguo mũthamaki wa Ashuri agaataha andũ a bũrũri wa Misiri na a bũrũri wa Kushi, amoimagarie marĩ njaga na marĩ magũrũ matheri, arĩa ethĩ na arĩa akũrũ, thũnũ ciao irĩ njaga; ũguo nĩguo Misiri gũgaaconorithio.
5 Gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Kuṣi tí wọ́n sì ń fi Ejibiti yangàn ni ẹ̀rù yóò dé bá tí a ó sì dójútì wọ́n.
Nao andũ arĩa mehokete Kushi na makegooca nĩ ũndũ wa Misiri nĩmakamaka na maconorithio.
6 Ní ọjọ́ náà àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ní etí Òkun yóò wí pé, ‘Wo ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí a ti gbẹ́kẹ̀lé, àwọn tí a sá tọ̀ lọ fún ìrànlọ́wọ́ àti ìtúsílẹ̀ láti ọwọ́ ọba Asiria! Báwo ni a ó ṣe sálà?’”
Hĩndĩ ĩyo nĩguo andũ arĩa maikaraga hũgũrũrũ-inĩ ici cia iria makoiga atĩrĩ, ‘Onei ũrĩa kũhanĩte kũrĩ arĩa tũtũire twĩhokete, acio tuorĩire kũrĩ o atĩ nĩguo matũteithie na matũhonokie kuuma kũrĩ mũthamaki wa Ashuri! Rĩu tũngĩkĩhonoka atĩa?’”

< Isaiah 20 >