< Isaiah 20 >
1 Ní ọdún tí olórí ogun, tí Sagoni ọba Asiria rán an, wá sí Aṣdodu, ó kọlù ú ó sì kó o—
Assyria lengpa Sargon in, a sepai jalam kaipa henga Philistine khopi Ashdod lo dinga thu apeh khum chun,
2 ní àkókò náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa ti ẹnu Isaiah ọmọ Amosi jáde. Ó sọ fún un pé, “Mú aṣọ ọ̀fọ̀ kúrò ní ara rẹ kí o sì bọ́ sálúbàtà kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ.” Ó sì ṣe bẹ́ẹ̀, ó ń lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà.
Pakai in Amoz chapa Isaiah henga aseijin, “Na von chu sutlhan lang na kengchot teni jongchu koidoh in.” Isaiah in akisei bang chun abolin, sagoh keoleh kengkeo in avahlen ahi.
3 Lẹ́yìn náà ni Olúwa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ mi Isaiah ti lọ káàkiri ní ìhòhò àti láì wọ bàtà fún ọdún mẹ́ta, gẹ́gẹ́ bí àmì àti àpẹẹrẹ sí Ejibiti àti Kuṣi,
Hichun Pakai in ahin seijin, “Ka sohpa Isaiah hi kumthum ahitai sagoh keo leh kengkeo va avalena hi. Hiche hi melchihna ahi-Egypt leh Ethiopia chunga hahsatna lentah kalhun sah ding vetsahna lim ahi.
4 bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọba Asiria yóò kó àwọn ìgbèkùn Ejibiti lọ ní ìhòhò àti láì wọ bàtà pẹ̀lú àwọn àtìpó Kuṣi, ọ̀dọ́ àti àgbà, pẹ̀lú ìbàdí ìhòhò—bí àbùkù Ejibiti.
Ajeh chu Assyria lengpan Egypt teleh Ethiopia te songkul tang dinga apui mang ding ahi. Sagoh keo leh kengchot beija avaleh sah ding, Egypt mite jumna dinga aneo alen atokeu uva alhat lesah ding ahi.
5 Gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Kuṣi tí wọ́n sì ń fi Ejibiti yangàn ni ẹ̀rù yóò dé bá tí a ó sì dójútì wọ́n.
Chuteng Philistine te lung linglao a umdiu ahi. Ajehchu amahon Ethiopia thanei akisonpiu va, chuleh akisamkai piu Egypt a kiletsah piu ahi.
6 Ní ọjọ́ náà àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ní etí Òkun yóò wí pé, ‘Wo ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí a ti gbẹ́kẹ̀lé, àwọn tí a sá tọ̀ lọ fún ìrànlọ́wọ́ àti ìtúsílẹ̀ láti ọwọ́ ọba Asiria! Báwo ni a ó ṣe sálà?’”
Hitia hi asei diu ahi, 'Hitobang hi Egypt te chunga ahunglhun theileh, eihon ipi agom kom phat inei diu ham? Assyria lengpa akona eihuhdoh dinguva Egypt te ina kisonpiu ahi.”