< Isaiah 19 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Ejibiti. Kíyèsi i, Olúwa gun àwọsánmọ̀ tí ó yára lẹ́ṣin ó sì ń bọ̀ wá sí Ejibiti. Àwọn ère òrìṣà Ejibiti wárìrì níwájú rẹ̀, ọkàn àwọn ará Ejibiti sì ti domi nínú wọn.
KA wanana no Aigupita. Aia hoi, ke holo la o Iehova maluna o ke ao mama, A hele mai koi ia i Aigupita. E haalulu auanei na akua kii o Aigupita imua o kona alo, E maule hoi ka naau o ko Aigupita iloko o lakou.
2 “Èmi yóò rú àwọn ará Ejibiti sókè sí ara wọn arákùnrin yóò bá arákùnrin rẹ̀ jà, aládùúgbò yóò dìde sí aládùúgbò rẹ̀, ìlú yóò dìde sí ìlú, ilẹ̀ ọba sí ilẹ̀ ọba.
E kahiko aku no wau i ko Aigupita, e kaua i ko Aigupita; E kaua no lakou, o kela mea keia mea i kona hoahanau iho, O kela mea keia mea i kona makamaka iho, O kekahi kulanakauhale i kekahi kulanakauhale, O kekahi aupuni i kekahi aupuni.
3 Àwọn ará Ejibiti yóò sọ ìrètí nù, èmi yóò sì sọ èrò wọn gbogbo di òfo; wọn yóò bá àwọn òrìṣà àti ẹ̀mí àwọn òkú sọ̀rọ̀, àwọn awoṣẹ́ àti àwọn abókùúsọ̀rọ̀.
E pau auanei ke aho o ko Aigupita iloko o lakou; E kookahuli au i ko lakou manao; Alaila, e huli lakou i ko lakou akuakii, I na mea namunamu, a me na mea ninau kupapau, a me na kupua.
4 Èmi yóò fi Ejibiti lé agbára àwọn ìkà amúnisìn lọ́wọ́, ọba aláìláàánú ni yóò jẹ ọba lé wọn lórí,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
E haawi aku no wau i ko Aigupita, i ka lima o ka haku oolea; A noho no kekahi alii oolea maluna o lakou, Wahi a ka Haku, o Iehova o na kaua.
5 Gbogbo omi inú odò ni yóò gbẹ, gbogbo ilẹ̀ àyíká odò ni yóò gbẹ tí yóò sì sáàpá.
E pau auanei ka wai o ka muliwai, E pio no hoi a maloo ke kahawai.
6 Adágún omi yóò sì di rírùn; àwọn odò ilẹ̀ Ejibiti yóò máa dínkù wọn yóò sì gbẹ. Àwọn koríko odò àti ìrẹ̀tẹ̀ yóò gbẹ,
E pilau auanei na muliwai, E pio, a maloo na auwai o Aigupita, A e mae wale no hoi ka naku a me ke kaluha.
7 àwọn igi ipadò Naili pẹ̀lú, tí ó wà ní orísun odò, gbogbo oko tí a dá sí ipadò Naili yóò gbẹ dànù tí yóò sì fẹ́ dànù tí kò sì ní sí mọ́.
O na papu ma kapa muliwai, a me ka waha o ka muliwai, A me na mea hua a pau ma ka muliwai, e maloo no ia mau mea, E puehu liilii ia no, a e nalowale.
8 Àwọn apẹja yóò sọkún kíkorò, àti gbogbo àwọn tí ó ń ju ìwọ̀ sínú odò; odò náà yóò sì máa rùn.
E kauiuhu no na lawaia, a me ka uwe iho, O ka poe a pau i kuu i ka makau ma ka muliwai, Ka poe i hohola i na upena maluna o na wai, E u auanei lakou.
9 Àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ọ̀gbọ̀ yóò kọminú àwọn ahunṣọ ọ̀gbọ̀ yóò sọ ìrètí nù.
O ka poe i hana i ke olona i kahiia, A me ka poe ulana i ka lole keokeo, E hilahila auanei lakou.
10 Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ aṣọ yóò rẹ̀wẹ̀sì, gbogbo àwọn oníṣẹ́ oṣù ni àìsàn ọkàn yóò ṣe.
E hehiia no na mea koikoi, A e kaumaha no hoi ka naau o ka poe paaua a pau.
11 Àwọn oníṣẹ́ Ṣoani ti di aláìgbọ́n, àwọn ọlọ́gbọ́n olùdámọ̀ràn Farao ń mú ìmọ̀ràn àìgbọ́n wá. Báwo ló ṣe lè sọ fún Farao pé, “Mo jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn ọba àtijọ́.”
He oiaio, ua naaupo na'lii o Zoana; O ka oleloao o na kakaolelo akamai o Parao, He olelo lapuwale ia. Pehea la oukou e olelo ai ia Parao, He keiki au na ka poe akamai, He keiki na na'lii kahiko?
12 Níbo ni àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn rẹ wà báyìí? Jẹ́ kí wọn fihàn ọ́ kí wọn sì sọ ọ́ di mí mọ̀ ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pinnu lórí Ejibiti.
Auhea lakou? Auhea kou poe akamai? Na lakou e hai mai ia oe, A e ike lakou i ka mea a Iehova o na kaua, E manao ai no Aigupita.
13 Àwọn ọmọ-aládé Ṣoani ti di aṣiwèrè, a ti tan àwọn ọmọ-aládé Memfisi jẹ; àwọn òkúta igun ilé tí í ṣe ti ẹ̀yà rẹ ti ṣi Ejibiti lọ́nà.
Ua naaupo no na'lii o Zoana, Ua puni na'lii o Nopa; Ua alakai hewa lakou i ko Aigupita, o na luna hoi o na ohana ona.
14 Olúwa ti da ẹ̀mí òòyì sínú wọn; wọ́n mú Ejibiti ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú ohun gbogbo tí ó ń ṣe, gẹ́gẹ́ bí ọ̀mùtí ti í ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú èébì rẹ̀.
Ua ninini mai o Iehova iwaena o lakou, i ka manao pihoihoi; A alakai hewa lakou i ko Aigupita ma kana mau hana a pau, Ua like me ka mea i ona, e hikaka ana maloko o kona luai.
15 Kò sí ohun tí Ejibiti le ṣe— orí tàbí ìrù, ọ̀wá ọ̀pẹ tàbí koríko odò.
Aole e hanaia ka hana ma Aigupita, Ka mea a ke poo e hiki ai ke hana, a me ka huelo; Ka lala pama, a me ka naku.
16 Ní ọjọ́ náà ni àwọn ará Ejibiti yóò dàbí obìnrin. Wọn yóò gbọ̀n jìnnìjìnnì pẹ̀lú ẹ̀rù nítorí ọwọ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí a gbé sókè sí wọn.
Ia la la, e like auanei ko Aigupita me na wahine, E makau no lakou a haalulu, No ke ka ana o ka lima o Iehova o na kaua, Ka mea ana e hooka mai ai maluna o lakou.
17 Ilẹ̀ Juda yóò sì di ẹ̀rù fún Ejibiti; gbogbo àwọn tí a bá ti dárúkọ Juda létí wọn ni yóò wárìrì, nítorí ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbèrò láti ṣe sí wọn.
E lilo no ka aina o ka Iuda, i mea e makau ai ko Aigupita, O na mea a pau o lakou i hoomanao ia wahi, e makau loa auanei, No ka manao ana o Iehova o na kaua, Ka mea ana i manao ai no lakou.
18 Ní ọjọ́ náà ìlú márùn-ún ní ilẹ̀ Ejibiti yóò sọ èdè àwọn ará Kenaani, wọn yóò sì búra àtìlẹ́yìn fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Ọ̀kan nínú wọn ni a ó sì máa pè ní ìlú ìparun.
Ia la la, elima no kulanakauhale ma ka aina o Aigupita, E olelo ana i ka olelo o Kanaana; A ma ka inoa o Iehova o na kaua lakou e hoohiki ai; A e kapaia kekahi o lakou, ke kulanakauhale o Heresa.
19 Ní ọjọ́ náà pẹpẹ kan yóò wà fún Olúwa ní àárín gbùngbùn Ejibiti, àti ọ̀wọ́n kan fún Olúwa ní etí bodè rẹ̀.
Ia la la e hanaia ke kuahu no Iehova, Iwaenakonu o ka aina o Aigupita, He puu no Iehova ma kolaila mau palena:
20 Yóò sì jẹ́ àmì àti ẹ̀rí sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ilẹ̀ Ejibiti. Nígbà tí wọ́n bá ké pe Olúwa nítorí àwọn aninilára wọn, yóò rán olùgbàlà àti olùgbèjà kan sí wọn tí yóò sì gbà wọ́n sílẹ̀.
He hoailona no ia, a he mea hoike hoi, No Iehova o na kaua, ma ka aina o Aigupita; No ko lakou hea ana ia Iehova i ko lakou hookaumahaia, A e hoouna mai oia no lakou i mea hoola, I mea mana hoi, nana lakou e hoopakele.
21 Báyìí ni Olúwa yóò sọ ara rẹ̀ di mí mọ̀ fún àwọn ará Ejibiti àti ní ọjọ́ náà ni wọn yóò gba Olúwa gbọ́. Wọn yóò sìn ín pẹ̀lú ẹbọ ọrẹ ìyẹ̀fun, wọn yóò jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa wọn yóò sì mú un ṣẹ.
Alaila, e ikeia o Iehova e ko Aigupita, A e hoomaopopo no ko Aigupita ia Iehova i kela la, A e malama lakou ia ia i ka mohai, a me ka alana; A e hoohiki lakou i ka hoohiki ana no Iehova, A e hooko io aku lakou.
22 Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn kan bá Ejibiti jà; yóò bá wọn jà yóò sì tún wò wọ́n sàn. Wọn yóò yípadà sí Olúwa, Òun yóò sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wọn yóò sì wò wọ́n sàn.
E hahau aku no o Iehova i ko Aigupita, E hahau aku no, a e hoola aku: A e huli no lakou ia Iehova, A e noiia oia e lakou, a e hoola mai oia ia lakou.
23 Ní ọjọ́ náà òpópónà kan yóò wá láti Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Asiria yóò lọ sí Ejibiti àti àwọn ará Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Ejibiti àti ará Asiria yóò jọ́sìn papọ̀.
Ia la la, e loaa no ke alanui, mai Aigupita aku a Asuria, A e hele no ko Asuria i Aigupita, A me ko Aigupita hoi i Asuria; A e malama pu no ko Aigupita me ko Asuria.
24 Ní ọjọ́ náà Israẹli yóò di ẹ̀kẹta pẹ̀lú Ejibiti àti Asiria, àní orísun ìbùkún ní ilẹ̀ ayé.
Ia la la, o ka Iseraela ke kolu, o Aigupita pu, a me Asuria, O ka pomaikai hoi iwaena o ka honua:
25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò bùkún wọn yóò wí pé, “Ìbùkún ni fún Ejibiti ènìyàn mi, Asiria iṣẹ́ ọwọ́ mi, àti Israẹli ìní mi.”
Ka mea a Iehova o na kaua i hoopomaikai ai, I ka i ana mai, Pomaikai ko'u poe kanaka, o ko Aigupita, A me ko Asuria hoi ka hana a ko'u mau lima, A me ka Iseraela ko'u hooilina.

< Isaiah 19 >