< Isaiah 19 >
1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Ejibiti. Kíyèsi i, Olúwa gun àwọsánmọ̀ tí ó yára lẹ́ṣin ó sì ń bọ̀ wá sí Ejibiti. Àwọn ère òrìṣà Ejibiti wárìrì níwájú rẹ̀, ọkàn àwọn ará Ejibiti sì ti domi nínú wọn.
Idibidi fi ea hou olelema: ne, sia: ne iasu da amane gala. Hina Gode da hehenane, mumobi amoga fila heda: le, Idibidi sogega manebe ba: sa. E manebeba: le, Idibidi ‘gode’ loboga hamoi liligi da beda: iba: le, yagugusa. Amola Idibidi fi dunu huluane da bagade beda: i.
2 “Èmi yóò rú àwọn ará Ejibiti sókè sí ara wọn arákùnrin yóò bá arákùnrin rẹ̀ jà, aládùúgbò yóò dìde sí aládùúgbò rẹ̀, ìlú yóò dìde sí ìlú, ilẹ̀ ọba sí ilẹ̀ ọba.
Hina Gode da amane sia: sa, “Na da hamobeba: le, Idibidi soge ganodini hisu gobele gegebe bagade ba: mu. Sama da ea sama amoma gegemu amola sosogo fi amo ganodini yolali da yolalia gegemu. Idibidi moilai bai bagade da eno Idibidi moilai bai bagade amoma gegemu amola hina bagade da eno hina bagade amo Idibidi soge ouligima: ne ludumu.
3 Àwọn ará Ejibiti yóò sọ ìrètí nù, èmi yóò sì sọ èrò wọn gbogbo di òfo; wọn yóò bá àwọn òrìṣà àti ẹ̀mí àwọn òkú sọ̀rọ̀, àwọn awoṣẹ́ àti àwọn abókùúsọ̀rọ̀.
Na da Idibidi dunu ilia ilegesu amo wadela: mu, amola ilia dogo denesi amo bu da: i dioma: ne hamomu. Ilia da ilia ‘gode’ loboga hamoi amola ilia gesami dasu amola bogoi a: silibu, amo ili fidima: ne adole ba: mu.
4 Èmi yóò fi Ejibiti lé agbára àwọn ìkà amúnisìn lọ́wọ́, ọba aláìláàánú ni yóò jẹ ọba lé wọn lórí,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Amola Na da Idibidi dunu, amo nimi bagade hame asigi gasa fi hina bagade ilima ouligima: ne, ilima imunu. Na, Hina Gode Bagadedafa, da sia: i dagoi.
5 Gbogbo omi inú odò ni yóò gbẹ, gbogbo ilẹ̀ àyíká odò ni yóò gbẹ tí yóò sì sáàpá.
Naile Hano da hale, gebewane sa: ili, hafoga: i dagoi ba: mu.
6 Adágún omi yóò sì di rírùn; àwọn odò ilẹ̀ Ejibiti yóò máa dínkù wọn yóò sì gbẹ. Àwọn koríko odò àti ìrẹ̀tẹ̀ yóò gbẹ,
Hano ea logo huluane da gebewane hale, gaha bagade nabimu. Saga: amola gagalobo da biomu.
7 àwọn igi ipadò Naili pẹ̀lú, tí ó wà ní orísun odò, gbogbo oko tí a dá sí ipadò Naili yóò gbẹ dànù tí yóò sì fẹ́ dànù tí kò sì ní sí mọ́.
Ha: i manu Naile Hano bega: sagai da biole, hafoga: le, foga gaguli asi dagoi ba: mu.
8 Àwọn apẹja yóò sọkún kíkorò, àti gbogbo àwọn tí ó ń ju ìwọ̀ sínú odò; odò náà yóò sì máa rùn.
Nowa da Naile Hano amoga menabo hiougili bidi lasu, da gogonomomu amola dimu. Bai ilia dimani amola menabo gasa: su da hamedei.
9 Àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ọ̀gbọ̀ yóò kọminú àwọn ahunṣọ ọ̀gbọ̀ yóò sọ ìrètí nù.
Nowa da abula amunasu da baligili se nabimu.
10 Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ aṣọ yóò rẹ̀wẹ̀sì, gbogbo àwọn oníṣẹ́ oṣù ni àìsàn ọkàn yóò ṣe.
Abula amunasu dunu amola noga: i hawa: hamosu dunu da wadela: lesi dagoi ba: mu.
11 Àwọn oníṣẹ́ Ṣoani ti di aláìgbọ́n, àwọn ọlọ́gbọ́n olùdámọ̀ràn Farao ń mú ìmọ̀ràn àìgbọ́n wá. Báwo ló ṣe lè sọ fún Farao pé, “Mo jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn ọba àtijọ́.”
Soua: ne moilai bai bagade ouligisu dunu, ilia da gagaoui. Idibidi soge baligili bagade dawa: su dunu da gagaoule sia: ne iaha. Ilia da hina bagade ema ogogole, ilia da hemone bagade dawa: su amola hemone hina bagade dunu iligaga fi dunu esala, amo sia: sa. Be amo da noga: i hame hou.
12 Níbo ni àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn rẹ wà báyìí? Jẹ́ kí wọn fihàn ọ́ kí wọn sì sọ ọ́ di mí mọ̀ ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pinnu lórí Ejibiti.
Idibidi hina bagade! Dia bagade dawa: su sia: ne iasu dunu da habila: ? Amabela: ? Ilia da Hina Gode Bagadedafa E da Idibidi amoma ilegei dawa: beba: le, dima adoma: bela: ?
13 Àwọn ọmọ-aládé Ṣoani ti di aṣiwèrè, a ti tan àwọn ọmọ-aládé Memfisi jẹ; àwọn òkúta igun ilé tí í ṣe ti ẹ̀yà rẹ ti ṣi Ejibiti lọ́nà.
Soua: ne moilai bai bagade amola Memefisi moilai bai bagade ilia ouligisu dunu da gagaoui dunu. Ilia da Idibidi fifi asi amo bisili ouligima: ne ilegei. Be ilia da udigili Idibidi dunuma ogogoi.
14 Olúwa ti da ẹ̀mí òòyì sínú wọn; wọ́n mú Ejibiti ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú ohun gbogbo tí ó ń ṣe, gẹ́gẹ́ bí ọ̀mùtí ti í ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú èébì rẹ̀.
Hina Gode da ilia asigi dawa: su olelebeba: le, ilia da ogogosu sia: ne iasu. Amaiba: le, Idibidi dunu fi da giadofale fawane hamosa. Amola ilia da adini ba: i dunu defele, feloale, ea isosu amoga sadenane dafasu agoane hamosa.
15 Kò sí ohun tí Ejibiti le ṣe— orí tàbí ìrù, ọ̀wá ọ̀pẹ tàbí koríko odò.
Dunu afae Idibidi soge ganodini, bagade gagui o hamedafa gagui, amo Idibidi fidima: ne hamedafa dawa:
16 Ní ọjọ́ náà ni àwọn ará Ejibiti yóò dàbí obìnrin. Wọn yóò gbọ̀n jìnnìjìnnì pẹ̀lú ẹ̀rù nítorí ọwọ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí a gbé sókè sí wọn.
Eso da doaga: mu amoga Idibidi fi dunu da uda defele beda: iwane ba: mu. Ilia da Hina Gode Bagadedafa Ea lobo ilua: le ilima se ima: ne lelebe ba: sea, ilia da beda: iba: le yagugumu.
17 Ilẹ̀ Juda yóò sì di ẹ̀rù fún Ejibiti; gbogbo àwọn tí a bá ti dárúkọ Juda létí wọn ni yóò wárìrì, nítorí ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbèrò láti ṣe sí wọn.
Idibidi dunu da eso huluane Hina Gode Bagadedafa da ilima se ima: ne ilegei, amo dawa: sea, ilia da Yuda fi dunu ilima bagadewane beda: mu.
18 Ní ọjọ́ náà ìlú márùn-ún ní ilẹ̀ Ejibiti yóò sọ èdè àwọn ará Kenaani, wọn yóò sì búra àtìlẹ́yìn fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Ọ̀kan nínú wọn ni a ó sì máa pè ní ìlú ìparun.
Amo eso doaga: sea, Hibulu sia: dafa da Idibidi moilai bai bagade biyaduyale ganodini sia: dalebe nabimu. Dunu amo moilai bai bagade ganodini esalebe, da sia: dafawanedafa sia: sea, ilia da Hina Gode Bagadedafa amo Ea Dioba: le sia: mu. Moilai afae amo biyaduyale ganodini amoga ilia da “Eso Moilai Bai Bagade” dio asulimu.
19 Ní ọjọ́ náà pẹpẹ kan yóò wà fún Olúwa ní àárín gbùngbùn Ejibiti, àti ọ̀wọ́n kan fún Olúwa ní etí bodè rẹ̀.
Amo eso doaga: sea, Hina Godema nodoma: ne, ‘oloda’ da Idibidi soge ganodini gagui dialebe ba: mu, amola igi duni bugi Godema modale ligiagai da Idibidi alalo legei amoga dialebe ba: mu.
20 Yóò sì jẹ́ àmì àti ẹ̀rí sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ilẹ̀ Ejibiti. Nígbà tí wọ́n bá ké pe Olúwa nítorí àwọn aninilára wọn, yóò rán olùgbàlà àti olùgbèjà kan sí wọn tí yóò sì gbà wọ́n sílẹ̀.
Oloda amola duni bugi ele da Hina Gode Bagadedafa da Idibidi soge ganodini esala, amo dawa: digima: ne olelesu liligi agoane ba: mu. Amola, Idibidi soge fi da enoga se nababeba: le, Hina Godema ili fidima: ne wele sia: sea, E da fidisu dunu ili gaga: ma: ne, ilima asunasimu.
21 Báyìí ni Olúwa yóò sọ ara rẹ̀ di mí mọ̀ fún àwọn ará Ejibiti àti ní ọjọ́ náà ni wọn yóò gba Olúwa gbọ́. Wọn yóò sìn ín pẹ̀lú ẹbọ ọrẹ ìyẹ̀fun, wọn yóò jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa wọn yóò sì mú un ṣẹ.
Hina Gode da Ea hou amo Idibidi dunuma olelemu. Amasea, ilia da Ea hou dafawaneyale dawa: mu, amola Ema sia: ne gadomu, amola Ema gobele salasu amola hahawane dogolegele iasu amo Ema gaguli misunu. Ilia da moloidafa hamoma: ne, Ema ilegele sia: mu, amola ilia ilegei noga: le hamomu.
22 Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn kan bá Ejibiti jà; yóò bá wọn jà yóò sì tún wò wọ́n sàn. Wọn yóò yípadà sí Olúwa, Òun yóò sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wọn yóò sì wò wọ́n sàn.
Hina Gode da Idibidi dunu ilima se imunu. Amasea, E da ili uhinisimu. Ilia da Ema sinidigisia, E da ilia sia: ne gadosu nababeba: le, ili uhinisimu.
23 Ní ọjọ́ náà òpópónà kan yóò wá láti Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Asiria yóò lọ sí Ejibiti àti àwọn ará Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Ejibiti àti ará Asiria yóò jọ́sìn papọ̀.
Amo eso da doaga: sea, logo bagade amo Idibidi amola Asilia amo disimusa: ba: mu. Amo soge aduna, ela fi dunu da amo logoga udigili ahoanebeba: le, ela fi dunu da gilisili Hina Godema nodone sia: ne gadomu.
24 Ní ọjọ́ náà Israẹli yóò di ẹ̀kẹta pẹ̀lú Ejibiti àti Asiria, àní orísun ìbùkún ní ilẹ̀ ayé.
Amo eso da doaga: sea, Isala: ili fi amola Idibidi fi amola Asilia fi ilia da defele ba: mu. Amola amo fi udiana, ilia hou hamobeba: le, osobo bagade fifi asi gala huluane da hahawane ba: mu.
25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò bùkún wọn yóò wí pé, “Ìbùkún ni fún Ejibiti ènìyàn mi, Asiria iṣẹ́ ọwọ́ mi, àti Israẹli ìní mi.”
Hina Gode Bagadedafa da ilima hahawane bagade ilegemu. E da amane sia: mu, “Na fi Idibidi dunu! Na da dilima hahawane bagade ilegemu. Asilia fi dunu! Na da dili hahamoi dagoi. Amola dilia, Isala: ili fi dunu. Dilia da Na ilegei fidafa. Dilia huluane, dilima Na da hahawane dogolegele hamoma: ne ilegei dagoi.”